Pular para o conteúdo
Publicidade

Orgulho

Por Bíblia Online

O orgulho é um dos pecados mais condenados na Bíblia. Deus resiste aos soberbos, mas dá graça aos humildes. A humildade é o caminho da honra verdadeira.

Deus resiste ao soberbo

A soberba precede a ruína e o orgulho antecede a queda. Deus abomina o coração altivo e promete humilhar quem se exalta.

Ìgbéraga í ṣáájú ìparun,

agídí ọkàn í ṣáájú ìṣubú.

Olúwa kórìíra gbogbo ẹni ń gbéraga lọ́kàn rẹ̀

mọ èyí dájú wọn lọ láìjìyà.

̀kan ó dàbí i ó dára lójú ènìyàn

ṣùgbọ́n ìgbẹ̀yìn a ṣokùnfà ikú.

Ìbẹ̀Olúwa ni ìkórìíra ibi

mo kórìíra ìgbéraga àti agídí,

ìwà ibi àti ̀rọ̀ ̀tàn.

Nígbà ìgbéraga , nígbà náà ni ìdójútì ,

ṣùgbọ́n pẹ̀ìrẹ̀lẹ̀ ni ọgbọ́n ń .

Nígbà ìgbéraga , nígbà náà ni ìdójútì ,

ṣùgbọ́n pẹ̀ìrẹ̀lẹ̀ ni ọgbọ́n ń .

Ìgbéraga ènìyàn a máa sọ ́ di ẹni ilẹ̀

ṣùgbọ́n onírẹ̀lẹ̀ ènìyàn a máa gba iyì kún iyì.

Ìgbéraga ènìyàn a máa sọ ́ di ẹni ilẹ̀

ṣùgbọ́n onírẹ̀lẹ̀ ènìyàn a máa gba iyì kún iyì.

Ṣáájú ìṣubú ọkàn ènìyàn a kọ́kọ́ máa gbéraga,

ṣùgbọ́n ìrẹ̀lẹ̀ ni ó máa ń ṣáájú ọlá.

Ṣáájú ìṣubú ọkàn ènìyàn a kọ́kọ́ máa gbéraga,

ṣùgbọ́n ìrẹ̀lẹ̀ ni ó máa ń ṣáájú ọlá.

Olúwa fa ilé onígbèéraga ya lulẹ̀,

ṣùgbọ́n ó pa ààlà opó onírẹ̀lẹ̀ mọ́ láìyẹ̀.

Humildade como caminho

Humilhai-vos diante do Senhor e Ele vos exaltará. A grandeza no Reino vem pelo serviço humilde, não pela autopromoção.

Ṣùgbọ́n ó fún ni oore-ọ̀fẹ́ i. Nítorí náà ni ìwé mímọ́ ṣe ,

"Ọlọ́run kọ ojú ìjà àwọn agbéraga,

ṣùgbọ́n ó fi oore-ọ̀fẹ́ fún àwọn onírẹ̀lẹ̀ ọkàn."

rẹ ara yín sílẹ̀ níwájú Olúwa, òun ó gbé yín ga.

Ṣùgbọ́n jẹ́ arákùnrin ó ń ṣe onírẹ̀lẹ̀ máa ṣògo ipò gíga. Àti ọlọ́rọ̀, ìrẹ̀sílẹ̀, nítorí ìtànná koríko ni yóò kọjá lọ.

Bẹ́̀ pẹ̀, ̀yin ̀dọ́, tẹríba fún àwọn alàgbà. Àní, gbogbo yín máa tẹríba fún ara yín fi ìrẹ̀lẹ̀ wọ ara yín aṣọ: nítorí,

"Ọlọ́run kọ ojú ìjà àwọn agbéraga,

ṣùgbọ́n ó ń fi oore-ọ̀fẹ́ fún àwọn onírẹ̀lẹ̀."

Nítorí náà, rẹ ara yin sílẹ̀ lábẹ́ ọwọ́ agbára Ọlọ́run, òun gbe yín ga lákokò. máa gbogbo àníyàn yín e; nítorí òun ń ṣe ìtọ́yín.

Nítorí ẹnikẹ́ni ó gbé ara rẹ̀ ga, ni a ó rẹ̀ sílẹ̀; ẹnikẹ́ni ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, ni a ó gbéga."

ṣe ohunkóhun nínú ìlépa ara tàbí ògo asán, ṣùgbọ́n ìrẹ̀lẹ̀ ọkàn olúkúlùkù ro àwọn ẹlòmíràn ẹni ti ó sàn ju òun lọ. olúkúlùkù yín ṣe ro ohun ti ara rẹ̀ nìkan, ṣùgbọ́n ti ẹlòmíràn pẹ̀.

Nínú ìbáṣepọ̀ yin pẹ̀àwọn ẹlòmíràn, ni irú ìlépa ọkàn náà ti Kristi Jesu.

Os perigos do orgulho

O orgulho cega, gera contendas e afasta de Deus. A Escritura adverte contra a soberba da vida e a vã glória mundana.

Nítorí ohun gbogbo ń bẹ nínú ayé: ìfẹ́kúfẹ̀́ ti ara, ìfẹ́kúfẹ̀́ ti ojú, àti ìgbéraga ti ohun ti ó àti ohun ó ṣe láti ̀dọ̀ Baba ṣe láti ọwọ́ ayé.

Nítorí náà, ẹni ó òun dúró, ó kíyèsára ó ma ba à ṣubú.

mo fi gbogbo nǹkan mo tọrẹ fún àwọn aláìní, mo fi ara mi fún ni láti sùn ṣùgbọ́n n ìfẹ́, èrè kan fún mi.

Àti àwọn ohun ayé ìyìn, àti àwọn ohun a kẹ́gàn, ni Ọlọ́run ti yàn, àní àwọn ohun , láti sọ àwọn ohun ó di asán. Nítorí ó ba à ẹnìkan yóò ṣògo níwájú rẹ̀.

"Ṣùgbọ́n jẹ́ ẹni ó ń ṣògo, ó máa ṣògo nínú Olúwa." Nítorí í ṣe ẹni ń yin ara rẹ̀ ni ó ìtẹ́wọ́gbà, ṣe ẹni Olúwa yìn.

Nígbà náà, ó fi kún un , "Èyí ti ó ti ọkàn ènìyàn jáde ni ń sọ ni di aláìmọ́. Nítorí láti inú ọkàn ènìyàn ni àwọn èrò búburú wọ̀nyí ti ń jáde : àgbèrè, olè, ìpànìyàn, panṣágà, ̀kánjúwà, odì yíyàn, ìtànjẹ, ìmọ-tara-ẹni, ìlara, ̀rọ̀ ̀yìn, ìgbéraga, òmùgọ̀. Gbogbo àwọn nǹkan búburú wọ̀nyí ń inú , àwọn ń sọ yín di aláìmọ́."

Ìgbéraga máa ń ìjà sílẹ̀ ni

ṣùgbọ́n ọgbọ́n nínú àwọn ń gba ìmọ̀ràn.

Èrè ìrẹ̀lẹ̀ àti ìbẹ̀Olúwa ni ọrọ̀ ọlá, àti ìyè.

Kìlọ̀ fún àwọn ó lọ́rọ̀ ayé ìsinsin yìí wọn ma ṣe gbéraga, bẹ́̀ ni wọn ṣe gbẹ́kẹ̀̀rọ̀ àìdánilójú, ṣe Ọlọ́run alààyè, ń fi ohun gbogbo fún wa lọ́pọ̀lọ́pọ̀ láti ;

O olhar de Deus

O Senhor não olha como o homem. Ele vê o coração e se agrada dos quebrantados de espírito e dos que tremem diante da sua Palavra.

Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Samuẹli , "ṣe wo ti ìrísí rẹ̀ tàbí ti gíga rẹ̀, nítorí èmi ti kọ̀ ́ sílẹ̀. Olúwa í wo ohun ènìyàn máa ń . Ènìyàn máa ń wo òde ara ṣùgbọ́n Olúwa máa ń wo ọkàn."

"ṣe halẹ̀;

ṣe jẹ́ ìgbéraga ti ẹnu yín jáde

nítorí Ọlọ́run olùmọ̀ ni Olúwa,

láti ̀dọ̀ rẹ̀ ni a ti ń wọn ìwà.

í ha á ṣe ọwọ́ mi ṣe nǹkan wọ̀nyí,

bẹ́̀ ni wọ́n ?"

ni Olúwa .

"Eléyìí ni ẹni mo :

ẹni náà ó rẹra rẹ̀ sílẹ̀ ó kẹ́dùn ọkàn rẹ̀,

ó wárìrì ̀rọ̀ mi.

Báyìí, èmi, Nebukadnessari fi ọpẹ́, mo gbé Ọlọ́run ga, mo fi ògo fún ọba ̀run, nítorí gbogbo nǹkan ó ṣe dára, gbogbo ̀rẹ̀ tọ́. Gbogbo àwọn ń rìn ìgbéraga ni ó le rẹ̀ sílẹ̀.

Ọba Israẹli dáhùn , "Sọ fún un , jẹ́ ẹni ń hámọ́ra halẹ̀ ẹni ń bọ́ sílẹ̀.’ "

máa inú kan náà ara yín. ṣe gbéraga, ṣùgbọ́n tẹ̀àwọn onírẹ̀lẹ̀. ṣe jẹ́ ọlọ́gbọ́n ojú ara yín.

Ṣùgbọ́n èso ti ̀ni ìfẹ́, ayọ̀, àlàáfíà, ìpamọ́ra, ìwà pẹ̀lẹ́, ìṣoore, ìgbàgbọ́, ìwà tútù, àti ìkóra-ẹni níjanu, òfin kan lòdì irú wọ̀nyí,

Seja o primeiro