Pular para o conteúdo
Publicidade

1 Reis 20

Beni-Hadadi kọlu Samaria

1 Beni-Hadadi ọba Aramu gbá gbogbo ogun rẹ̀ jọ. Ọba méjìlélọ́gbọ̀n ń bẹ pẹ̀rẹ̀ àti ẹṣin àti kẹ̀kẹ́, ó gòkè lọ, ó ti Samaria, ó kọlù ú. 2 Ó rán àwọn ìránṣẹ́ ìlú Ahabu ọba Israẹli , "Báyìí ni Beni-Hadadi , 3 Fàdákà àti wúrà rẹ tèmi ni, àti àwọn ó dára jùlọ nínú àwọn aya rẹ àti àwọn ọmọ rẹ tèmi ni wọ́n.’ "

4 Ọba Israẹli a lóhùn , "Gẹ́gẹ́ ìwọ ṣe olúwa mi ọba, èmi àti ohun gbogbo mo tìrẹ ni."

5 Àwọn oníṣẹ́ náà tún padà , wọ́n , "Báyìí ni Beni-Hadadi sọ , Mo ránṣẹ́ láti béèrè fún fàdákà rẹ àti wúrà rẹ, àwọn aya rẹ àti àwọn ọmọ rẹ. 6 Ṣùgbọ́n ìwòyí ̀la, èmi yóò rán àwọn ìránṣẹ́ mi láti ilé rẹ àti ilé àwọn ìránṣẹ́ rẹ. Wọn yóò gba gbogbo ohun ó dára lójú rẹ, wọn yóò o lọ.’ "

7 Nígbà náà ni ọba Israẹli pe gbogbo àwọn àgbàgbà ìlú, ó fún wọn , "wo ọkùnrin yìí ti ń fẹ́ ìyọnu! Nígbà ó ránṣẹ́ fún àwọn aya mi, àti fún àwọn ọmọ mi, àti fún fàdákà mi, àti fún wúrà mi, èmi fi ú."

8 Àwọn àgbàgbà àti gbogbo ènìyàn a lóhùn , "ṣe fi etí tirẹ̀ tàbí ó gbà fún un."

9 Nígbà náà ni ó sọ fún àwọn oníṣẹ́ Beni-Hadadi , "Sọ fún olúwa mi ọba , Ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò ṣe ohun gbogbo ó ránṣẹ́ fún látètèkọ́ṣe, ṣùgbọ́n nǹkan yìí ni èmi le ṣe.’ " Wọ́n padà lọ, wọ́n èsì padà fún Beni-Hadadi.

10 Beni-Hadadi tún rán oníṣẹ́ mìíràn Ahabu , "àwọn òrìṣà ó ṣe bẹ́̀ mi àti bẹ́̀ lọ pẹ̀eruku Samaria yóò fún ìkúnwọ́ fún gbogbo ènìyàn ń tẹ̀mi."

11 Ọba Israẹli dáhùn , "Sọ fún un , jẹ́ ẹni ń hámọ́ra halẹ̀ ẹni ń bọ́ sílẹ̀.’ "

12 Beni-Hadadi gbọ́ ̀rọ̀ yìí nígbà òun àti àwọn ọba ń mu ọtí nínú àgọ́ wọn, ó pàṣẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ , "ṣígun ìlú náà." Bẹ́̀ ni wọ́n ṣe tan láti kọlu ìlú náà.

Ahabu ṣẹ́gun Beni-Hadadi

13 kíyèsi i, wòlíì kan tọ Ahabu ọba Israẹli , ó , "Báyìí ni Olúwa : Ìwọ gbogbo ̀pọ̀lọpọ̀ ogun yìí? Èmi yóò fi wọ́n lọ́wọ́ lónìí, nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ Èmi ni Olúwa.’ "

14 Ahabu béèrè , "Ṣùgbọ́n ta ni yóò ṣe èyí?"

Wòlíì náà dáhùn , "Èyí ni ohun Olúwa : Nípa ìpẹ́̀rẹ̀ àwọn ìjòyè ìgbèríko.’ "

Nígbà náà ni ó . "Ta ni yóò bẹ̀rẹ̀ ogun náà?"

Wòlíì dalóhùn , "Ìwọ ni yóò ṣe é."

15 Nígbà náà ni Ahabu ka àwọn ìjòyè kéékèèké ìgbèríko, wọ́n jẹ́ igba ó méjìlélọ́gbọ̀n (232). Nígbà náà ni ó gbogbo àwọn ọmọ Israẹli tókù jọ, gbogbo wọn jẹ́ ̀́dẹ́gbàárin (7,000). 16 Wọ́n jáde lọ ̀sán gangan, nígbà Beni-Hadadi àti àwọn ọba méjìlélọ́gbọ̀n (32) ń ràn án lọ́wọ́ ń mu àmupara nínú àgọ́. 17 Àwọn ìjòyè kéékèèké ìgbèríko tètè kọ́ jáde lọ.

Beni-Hadadi ránṣẹ́ jáde, wọ́n sọ fún un , "Àwọn ọkùnrin ń ti Samaria jáde ."

18 Ó , "wọ́n ti àlàáfíà jáde , wọn láààyè; ti ogun ni wọ́n jáde, wọn láààyè."

19 Àwọn ìjòyè kéékèèké wọ̀nyí ti àwọn ìjòyè ìgbèríko jáde ti ìlú , àti ogun ó tẹ̀wọn. 20 Olúkúlùkù pa ọkùnrin kọ̀̀kan. Àwọn ará Aramu , Israẹli lépa wọn. Ṣùgbọ́n Beni-Hadadi ọba Aramu sálà lórí ẹṣin pẹ̀àwọn ẹlẹ́ṣin. 21 Ọba Israẹli jáde lọ, ó kọlu àwọn ẹṣin àti kẹ̀kẹ́, ó pa àwọn ará Aramu ̀pọ̀lọpọ̀.

22 Lẹ́yìn náà, wòlíì náà sọ́dọ̀ ọba Israẹli, ó , "Lọ, ara rẹ gírí, o mọ̀, o wo ohun ìwọ yóò ṣe, nítorí àmọ́dún ọba Aramu yóò tún gòkè tọ̀ ́ ."

23 Àwọn ìránṣẹ́ ọba Aramu fún un , "Ọlọ́run wọn, ọlọ́run òkè ni. Ìdí nìyìí wọ́n ṣe agbára lọ. Ṣùgbọ́n a wọn pẹ̀tẹ́lẹ̀, àwa yóò agbára wọ́n lọ dájúdájú. 24 Nǹkan yìí ni o ṣe, àwọn ọba kúrò, olúkúlùkù kúrò ipò rẹ̀, o fi baálẹ̀ ipò wọn. 25 o tún ogun jọ fún ara rẹ èyí ó ti sọnù; ẹṣin fún ẹṣin, kẹ̀kẹ́ fún kẹ̀kẹ́; a Israẹli pẹ̀tẹ́lẹ̀. Nítòótọ́ àwa yóò agbára wọ́n lọ." Ó gba tiwọn, ó ṣe bẹ́̀.

26 Ó ṣe àmọ́dún, Beni-Hadadi ka iye àwọn ará Aramu, ó gòkè lọ Afeki, láti Israẹli jagun. 27 Nígbà a ka àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n pèsè oúnjẹ, wọ́n lọ pàdé wọn. Àwọn ọmọ Israẹli òdìkejì wọn gẹ́gẹ́ agbo ọmọ ewúrẹ́ kékeré méjì, nígbà àwọn ará Aramu kún ilẹ̀ náà.

28 Ènìyàn Ọlọ́run kan gòkè , ó sọ fún ọba Israẹli , "Báyìí ni Olúwa : Nítorí àwọn ará Aramu Olúwa, Ọlọ́run òkè ni, ṣùgbọ́n òun í ṣe Ọlọ́run àfonífojì, nítorí náà èmi ó fi gbogbo ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn yìí lọ́wọ́, ̀yin yóò mọ̀ , Èmi ni Olúwa.’ "

29 Wọ́n òdìkejì ara wọn fún ọjọ́ méje, àti ọjọ́ keje, wọ́n pàdé ogun. Àwọn ọmọ Israẹli pa ̀kẹ́ márùn-ún (100,000) ẹlẹ́ṣẹ̀ nínú àwọn ará Aramu ọjọ́ kan. 30 Àwọn tókù àsálà lọ Afeki, sínú ìlú odi ti ẹgbàá mẹ́tàlá ẹgbẹ̀rún (27,000) nínú wọn. Beni-Hadadi sálọ sínú ìlú, ó fi ara pamọ́ sínú ìyẹ̀.

31 Àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ fún un , "ó, a ti gbọ́ àwọn ọba ilẹ̀ Israẹli jẹ́ ọba aláàánú, mo bẹ̀ ́ jẹ́ àwa ó tọ̀ ́ lọ pẹ̀aṣọ ̀fọ̀ ̀gbẹ́ wa, àti okùn orí wa . Bóyá òun yóò gba ̀rẹ ."

32 Bẹ́̀ ni wọ́n di aṣọ ̀fọ̀ mọ́ ̀gbẹ́ wọn, wọ́n fi okùn orí wọn , wọ́n tọ ọba Israẹli , wọ́n , "Ìránṣẹ́ rẹ Beni-Hadadi , Èmi bẹ̀ ́ jẹ́ èmi ó .’ "

Ọba dáhùn , "Ó ń bẹ láààyè ? Arákùnrin mi ni òun."

33 Àwọn ọkùnrin náà ṣe àkíyèsí gidigidi, wọ́n yára gbá ̀rọ̀ rẹ̀ , wọ́n , "Bẹ́̀ ni, Beni-Hadadi arákùnrin rẹ."

Ọba , "lọ u ." Nígbà Beni-Hadadi jáde tọ̀ ́ , Ahabu u gòkè sínú kẹ̀kẹ́.

34 Beni-Hadadi , "Èmi yóò àwọn ìlú baba mi ti gbà lọ́wọ́ baba rẹ padà, ìwọ le la ̀fún ara rẹ Damasku, baba mi ti ṣe Samaria."

Ahabu , "Èmi yóò rán lọ pẹ̀májẹ̀yìí." Bẹ́̀ ni ó ba májẹ̀, ó rán an lọ.

35 Nípa ̀rọ̀ Olúwa, ọkùnrin kan nínú àwọn ọmọ àwọn wòlíì fún èkejì rẹ̀ , "Jọ̀ ́, ," ṣùgbọ́n ó kọ̀ láti ú.

36 Nígbà náà ni ó , "Nítorí ìwọ gba ohùn Olúwa gbọ́, kíyèsi i, ìwọ kúrò ̀dọ̀ mi, kìnnìún yóò pa ́." ó ti jáde lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, kìnnìún kan i, ó pa á.

37 Wòlíì náà ọkùnrin mìíràn, ó fún un , "Jọ̀ ́, ." Bẹ́̀ ni ọkùnrin náà ú, ó pa á lára. 38 Wòlíì náà lọ, ó dúró de ọba ojú ̀. Ó pa ara rẹ̀ fífi eérú bo ojú. 39 ọba ti ń rékọjá, wòlíì náà i, ó , "Ìránṣẹ́ rẹ jáde wọ àárín ogun lọ, ẹnìkan ̀dọ̀ mi pẹ̀ìgbèkùn kan, ó , Pa ọkùnrin yìí mọ́. a fẹ́ , ̀rẹ yóò lọ dípò ̀rẹ̀, tàbí ìwọ san tálẹ́ǹtì fàdákà kan.40 Nígbà ìránṣẹ́ rẹ̀ ìṣe níhìn-ín àti lọ́hùn ún, a fẹ́ ."

Ọba Israẹli fún un , "Bẹ́̀ ni ìdájọ́ rẹ yóò , ìwọ fúnra rẹ̀ ti a."

41 Nígbà náà ni wòlíì náà yára, ó eérú kúrò ojú rẹ̀, ọba Israẹli mọ̀ ́n ̀kan nínú àwọn wòlíì ni ó ń ṣe. 42 Ó fún ọba , "Báyìí ni Olúwa : Ìwọ ti jọ̀wọ́ ọkùnrin èmi ti yàn ìparun pátápátá lọ́wọ́ lọ. Nítorí náà, ̀rẹ yóò lọ fún ̀rẹ, ènìyàn rẹ fún ènìyàn rẹ̀.’ " 43 Ọba Israẹli lọ ilé rẹ̀ wíwú gbọ́, inú rẹ bàjẹ́, ó Samaria.

Veja também