Publicidade

Amós 4

Israẹli yípadà Ọlọ́run

1 gbọ́ ̀rọ̀ yìí, ̀yin màlúù Baṣani lórí òkè Samaria,

̀yin obìnrin ó ń ni tálákà lára,

ó ń tẹ aláìní mọ́lẹ̀, ó fún ọkọ rẹ̀, "Gbé a mu!"

2 Olúwa Olódùmarè ti fi ìwà mímọ́ rẹ̀ búra:

"Àkókò náà yóò nítòótọ́

nígbà a ó fi ìwọ̀ un yín lọ,

ẹni ó kẹ́yìn pẹ̀ìwọ̀ ẹja.

3 Ẹni kọ̀̀kan yín yóò jáde lọ

gba àárín odi yíya

a ó e yín Harmoni,"

ni Olúwa .

4 "lọ Beteli láti dẹ́ṣẹ̀;

lọ Gilgali dẹ́ṣẹ̀ i.

ẹbọ sísun yín láràárọ̀ ,

ìdámẹ́wàá yín ọdọọdún mẹ́ta.

5 ̀rẹ́ ìdúpẹ́ ìyẹ̀fun ìwúkàrà ti a sun

ọrẹ àtinúwá

lọ fi wọ́n yangàn, ̀yin ènìyàn Israẹli,

nítorí èyí ni fẹ́ láti ṣe,"

ni Olúwa Olódùmarè .

6 "Èmi fún un yín mímọ́ eyín gbogbo ìlú yín,

àti àìní oúnjẹ gbogbo ibùgbé yín,

síbẹ̀, ̀yin yípadà sọ́dọ̀ mi,"

ni Olúwa .

7 "Àti pẹ̀mo òjò dúró

nígbà ìkórè ku oṣù mẹ́ta.

Mo rán òjò ibùgbé kan

ṣùgbọ́n rọ̀ ìlú mìíràn.

Oko kan òjò;

àwọn mìíràn ó gbẹ.

8 Àwọn ènìyàn ń rìn láti ìlú kan ìlú mìíràn fún omi

wọn mu tẹ́ wọn lọ́rùn,

síbẹ̀ ̀yin padà ̀dọ̀ mi,"

ni Olúwa .

9 "Lọ́pọ̀ ìgbà ni mo kọlu ọgbà àti ọgbà àjàrà yín

mo fi ìrẹ̀dànù àti ìmúwòdù wọ́n.

Eṣú jẹ igi ̀pọ̀tọ́ àti igi olifi yín,

síbẹ̀ ̀yin yípadà mi,"

ni Olúwa .

10 "Mo rán àjàkálẹ̀-ààrùn i yín

mo ti ṣe Ejibiti.

Mo fi idà pa àwọn ̀dọ́mọkùnrin yín.

Pẹ̀àwọn ẹṣin a ìgbèkùn.

Mo kún imú yín fún òórùn ibùdó yín,

síbẹ̀ ̀yin yípadà mi,"

ni Olúwa .

11 "Mo ti ṣubú nínú yín,

Ọlọ́run ti bi Sodomu àti Gomorra ṣubú

̀yin dàbí ògúnná a fa yọ kúrò nínú iná,

síbẹ̀ ̀yin yípadà mi,"

ni Olúwa .

12 "Nítorí náà, èyí ni ohun èmi yóò ṣe i yín, Israẹli,

àti nítorí èmi ó ṣe èyí i yín,

múra láti pàdé Ọlọ́run yín, ̀yin Israẹli."

13 Ẹni ó àwọn òkè

ó afẹ́fẹ́

ó fi èrò rẹ̀ hàn ènìyàn,

ẹni ó yípadà òkùnkùn

ó tẹ ibi gíga ayé.

Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-