Publicidade

Atos 22

1 "̀yin ará àti baba, gbọ́ ẹnu mi nísinsin yìí."

2 Nígbà wọ́n gbọ́ ó ń wọn sọ̀rọ̀ ni èdè Aramaiki, wọ́n túbọ̀ dákẹ́ jẹ́́.

Nígbà náà ni ó , 3 "Júù ni èmi í ṣe, a mi ni Tarsu ìlú kan Kilikia, ṣùgbọ́n a tọ́ mi dàgbà ni ìlú yìí. abẹ́ ẹsẹ̀ Gamalieli ni a gbé kọ́ mi òfin àwọn baba wa, mo ìtara fún Ọlọ́run àní gẹ́gẹ́ gbogbo yin ni òní. 4 Mo ṣe inúnibíni àwọn ènìyàn ń tọ ̀yìí ojú ikú wọn, mo tọkùnrin tobìnrin wọ́n, mo fi wọ́n sínú túbú, 5 àní olórí àlùfáà pẹ̀gbogbo àjọ àwọn alàgbà jẹ́ mi ̀. Mo tilẹ̀ gba ìwé àṣẹ lọ́wọ́ wọn lọ sọ́dọ̀ àwọn arákùnrin wọn Damasku láti àwọn ó níbẹ̀ dídè Jerusalẹmu, láti jẹ wọ́n .

6 "èmi súnmọ́ etí Damasku níwọ̀n ọjọ́-kanrí, lójijì ìmọ́lẹ̀ ńlá láti ̀run mọ́lẹ̀ mi . 7 Mo ṣubú lulẹ̀, mo gbọ́ ohùn kan ó fún mi , Saulu, Saulu èéṣe ìwọ fi ń ṣe inúnibíni mi?

8 "Mo béèrè , Ta ni ìwọ, Olúwa?

"Ó mi lóhùn , Èmi ni Jesu Nasareti, ẹni ìwọ ń ṣe inúnibíni . 9 Àwọn ó pẹ̀mi ìmọ́lẹ̀ náà nítòótọ́, ṣùgbọ́n wọn gbọ́ ohùn ẹni ń mi sọ̀rọ̀.

10 "Mo béèrè , Kín ni èmí ó ṣe, Olúwa?

"Olúwa fún mi , Dìde, o lọ Damasku; níbẹ̀ ni a ó ti sọ ohun gbogbo fún a yàn fún láti ṣe. 11 Àwọn ó pẹ̀mi lọ́wọ́ wọ Damasku lọ nítorí èmi ríran nítorí ìtànṣán ìmọ́lẹ̀ náà ti fọ́ mi ojú.

12 "Ọkùnrin kan a ń Anania tọ̀ , ẹni jẹ́ olùfọkànsìn ti òfin, ó lórúkọ rere lọ́dọ̀ gbogbo àwọn Júù ó ń gbé ibẹ̀. 13 Ó dúró , ó fún mi , Arákùnrin Saulu, gba ìríran!ẹsẹ̀ kan náà, mo ṣí ojú òkè mo i.

14 "Nígbà náà ni ó : Ọlọ́run àwọn baba wa ti yàn ́ láti mọ ìfẹ́ rẹ̀, àti láti ri Ẹni òdodo náà, àti láti gbọ́ ̀rọ̀ láti ẹnu rẹ̀. 15 Ìwọ yóò jẹ́ ẹlẹ́rìí rẹ̀ fún gbogbo ènìyàn, nínú ohun ìwọ ìwọ ti gbọ́. 16 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, kín ni ìwọ ń dúró ? Dìde, a bamitiisi rẹ̀, ó wẹ ̀ṣẹ̀ rẹ , ó máa pe orúkọ rẹ̀.’

17 "Nígbà mo padà Jerusalẹmu mo ǹ gbàdúrà tẹmpili, mo bọ́ ojúran, 18 mo Olúwa, ó ń sọ̀rọ̀ fún mi , Kíá! Jáde kúrò Jerusalẹmu kánkán, nítorí wọn yóò gba ̀rẹ nípa mi gbọ́.’

19 "Èmi , Olúwa, àwọn ènìyàn wọ̀nyí pàápàá mọ̀ èmi ti lọ láti inú Sinagọgu kan èkejì láti máa sọ wọ́n sínú túbú àti láti máa lu àwọn ó gbà ́ gbọ́. 20 Nígbà a ta ̀jẹ̀ Stefanu ẹlẹ́rìí rẹ sílẹ̀, èmi náà pẹ̀dúró níbẹ̀, mo ohùn ikú rẹ̀, mo ń ṣe ìtọ́aṣọ àwọn ẹni ó pa á.

21 "Nígbà náà ni Olúwa fún mi , Máa lọ; nítorí èmi ó rán àwọn aláìkọlà lókèèrè réré."

Paulu ọmọ ìbílẹ̀ Romu

22 Wọ́n fi etí ̀rọ̀ Paulu títí ó fi sọ ̀rọ̀ yìí. Nígbà yìí ni wọ́n gbé ohùn wọn sókè, wọ́n kígbe , "mu ẹni yìí kúrò láyé! yẹ ó láààyè!"

23 wọ́n ti ń kígbe, wọ́n ń aṣọ wọn káàkiri, wọ́n ń ku eruku ojú ̀run, 24 olórí ogun pàṣẹ a Paulu sínú àgọ́ àwọn ológun. Ó pàṣẹ wọ́n ó ú, wọn fi ̀rọ̀ wa lẹ́nu , òun ba à mọ ìdí wọ́n fi ń kígbe e lórí bẹ́̀. 25 wọ́n fi ọṣán é, Paulu balógun ̀rún ó dúró í , "Ó ha tọ́ fún yín láti na ẹni i ṣe ará Romu ni àìdálẹ́bi ?"

26 Nígbà balógun ̀rún gbọ́ èyí, ó lọ fún olórí ogun , "Kín ni ó fẹ́ ṣe yìí: nítorí ọkùnrin yìí ará Romu i ṣe?"

27 Alábojútó-ogun , ó Paulu , "Sọ fún mi, ará Romu ni ìwọ jẹ́ ?"

Ó , "Bẹ́̀ ni."

28 Alábojútó-ogun dáhùn , "Owó púpọ̀ ni mo fi ra ọlá ìbílẹ̀ yìí."

Paulu , "Ṣùgbọ́n a mi sínú rẹ̀ ni."

29 Nítorí náà àwọn ó múra láti fi ̀rọ̀ wa lẹ́nu fàsẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀: lójúkan náà. Olórí ogun pẹ̀bẹ̀nígbà ó mọ̀ ọmọ ìbílẹ̀ Romu Paulu i ṣe, àti nítorí ó é.

Níwájú àwọn ìgbìmọ̀

30 ọjọ́ kejì, nítorí olórí ogun fẹ́ mọ̀ dájúdájú ohun àwọn Júù ń fi Paulu sùn , ó u sílẹ̀, ó pàṣẹ àwọn olórí àlùfáà àti gbogbo ìgbìmọ̀ péjọ, nígbà náà ni ó Paulu sọ̀kalẹ̀, ó un dúró níwájú wọn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-