Pular para o conteúdo
Publicidade

Resultados da busca por "salvação"

50 resultados encontrados

  1. Neemias 7

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 7
    Mostrando versículos 9–48 de 73

    9Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá (372)

    13Sattu jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀rin ó lé márùn-ún (845)

    48Lebana, Hagaba, Ṣalmai,

  2. Gálatas 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 5–22 de 24

    51.5: Ro 16.27.ẹni tí ògo wà fún láé àti láéláé. Àmín.

    6Ó yà mi lẹ́nu pé ẹ tètè yapa kúrò lọ́dọ̀ ẹni tí ó pè yín sínú oore-ọ̀fẹ́ Kristi, sí ìyìnrere mìíràn.

    22Mo sì jẹ́ ẹni tí a kò mọ̀ lójú fún àwọn ìjọ tí ó wà nínú Kristi ni Judea.

  3. Jó 8

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 8
    Mostrando versículos 3–17 de 22

    3Ọlọ́run a ha máa yí ìdájọ́ po bí?Tàbí Olódùmarè a máa gbé ẹ̀bi fún aláre?

    14Àbá ẹni tí a ó kèé kúrò,àti ìgbẹ́kẹ̀lé ẹni tí ó dàbí ilé aláǹtakùn.

    17Gbòǹgbò rẹ̀ ta yí ebè ká,ó sì wó ibi òkúta wọ̀n-ọn-nì.

  4. Deuteronômio 14

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 14
    Mostrando versículos 5–17 de 29

    5àgbọ̀nrín, èsúró, etu, àgóró, ẹfọ̀n, ìgalà àti àgùntàn igbó.

    16onírúurú òwìwí,

    17òwìwí ọ̀dàn, àkàlà, ìgò,

  5. Romanos 7

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 7
    Mostrando versículos 5–24 de 25

    57.5: Ro 6.13,21; 8.8; Jk 1.15.Nítorí ìgbà tí a wa nípa ti ara, ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ nípa ti òfin, ma ń ṣiṣẹ́ nínú wa, tí a sì ń so èso tí ó yẹ fún ikú.

    107.10: Le 18.5; Ro 10.5.Mo ṣàkíyèsí pé òfin tí ó yẹ kí ó mú ìyè wá ni ó padà mú ikú wá.

    247.24: Ro 6.6; Kl 2.11.Èmi ẹni òsì! Ta ni yóò ha gbà mí sílẹ̀ lọ́wọ́ ara kíkú yìí?

  6. Jeremias 48

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 48
    Mostrando versículos 6–23 de 47

    6Sá! Àsálà fún ẹ̀mí yín;kí ẹ sì dàbí aláìní ní aginjù.

    22sórí Diboni, Nebo àti Beti-Diblataimu,

    23sórí Kiriataimu, Beti-Gamu àti Beti-Meoni,

  7. Gênesis 25

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 25
    Mostrando versículos 10–15 de 34

    10inú oko tí Abrahamu rà lọ́wọ́ ara Hiti yìí ni a sin Abrahamu àti Sara aya rẹ̀ sí.

    14Miṣima, Duma, Massa,

    15Hadadi, Tema, Jeturi,Nafiṣi, àti Kedema.

  8. 1 Timóteo 4

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 4
    Mostrando versículos 5–13 de 16

    5Nítorí tí a fi ọ̀rọ̀ Ọlọ́run àti àdúrà yà sí mímọ́.

    11Nǹkan wọ̀nyí ni kí ó máa paláṣẹ kí ó máa kọ́ni.

    13Títí èmi ó fi dé, máa fiyèsí kíkàwé àti ìgbaniníyànjú àti ìkọ́ni.

  9. Josué 15

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 15
    Mostrando versículos 26–40 de 63

    26Amamu, Ṣema, Molada,

    34Sanoa, Eni-Gannimu, Tapua, Enamu,

    40Kabboni, Lamasi, Kitlisi,

  10. Eclesiastes 2

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 2
    Mostrando versículos 2–22 de 26

    2"Mo wí fún ẹ̀rín pé òmùgọ̀ ni. Àti fún ìre-ayọ̀ pé kí ni ó ń ṣe?"

    16Nítorí pé ọlọ́gbọ́n ènìyàn, gẹ́gẹ́ bí i òmùgọ̀, a kì yóò rántí rẹ̀ fún ìgbà pípẹ́;gbogbo wọn ni yóò di ohun ìgbàgbé ní ọjọ́ tó ń bọ̀.Ikú tí ó pa aṣiwèrè náà ni yóò pa ọlọ́gbọ́n ènìyàn.

    22Kí ni ohun tí ènìyàn rí gbà fún gbogbo wàhálà àti ìpọ́njú tí ó fi ṣiṣẹ́ lábẹ́ oòrùn?

  11. Números 10

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 10
    Mostrando versículos 11–34 de 36

    11Ní ogúnjọ́ oṣù kejì, ní ọdún kejì ni ìkùùkuu kúrò lórí tabanaku ẹ̀rí.

    26Pagieli ọmọ Okanri ni ìpín ti ẹ̀yà Aṣeri,

    34Ìkùùkuu Olúwa wà lórí wọn lọ́sàn nígbà tí wọ́n gbéra kúrò ní ibùdó.

  12. Ester 9

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 9
    Mostrando versículos 8–21 de 32

    8Porata, Adalia, Aridata,

    9Parmaṣta, Arisai, Aridai àti Faisata.

    21láti lè máa ṣe àjọyọ̀ ní ọjọ́ kẹrìnlá àti ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù Addari ní ọdọọdún.

  13. Gênesis 31

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 31
    Mostrando versículos 2–45 de 55

    2Jakọbu sì ṣàkíyèsí pé ìwà Labani sí òun ti yí padà sí ti àtẹ̀yìnwá.

    22Ní ọjọ́ kẹta ni Labani gbọ́ pé Jakọbu ti sálọ.

    45Jakọbu sì mú òkúta kan ó sì gbé e dúró bí ọ̀wọ́n.

  14. Levítico 6

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 6
    Mostrando versículos 13–27 de 30

    13Iná gbọdọ̀ máa jó lórí pẹpẹ títí, kò gbọdọ̀ kú.

    26Àlùfáà tó rú ẹbọ náà ni kí ó jẹ ẹ́, ibi mímọ́ ni kí ó ti jẹ ẹ́, ní àgbàlá àgọ́ ìpàdé.

    27Ohunkóhun tí ó bá kàn án yóò di mímọ́, bí ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ bá sì ta sí ara aṣọ kan, ẹ gbọdọ̀ fọ̀ ọ́ ní ibi mímọ́.

  15. Josué 21

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 21
    Mostrando versículos 14–30 de 45

    14Jattiri, Eṣitemoa,

    15Holoni àti Debiri,

    30Láti ara ẹ̀yà Aṣeri ni wọ́n ti fún wọn níMiṣali, àti Abdoni,

  16. Romanos 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 1–16 de 31

    1Ǹjẹ́ àǹfààní wo ní Júù ní? Tàbí kín ni èrè ilà kíkọ?

    6Kí a má rí i. Bí bẹ́ẹ̀ bá ni, Ọlọ́run yóò ha ṣe lè dájọ́ aráyé?

    16ìparun àti ìpọ́njú wà lọ́nà wọn.

  17. 1 Timóteo 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 5–19 de 20

    5Ète àṣẹ náà ni ìfẹ́ ti ń jáde wá láti inú ọkàn mímọ́ àti ẹ̀rí ọkàn rere àti ìgbàgbọ́ àìṣẹ̀tàn.

    6Àwọn ẹlòmíràn ti yapa kúrò tí wọ́n sì yà sápá kan sí ọ̀rọ̀ asán.

    19máa ní ìgbàgbọ́ àti ẹ̀rí ọkàn rere. Èyí ti àwọn mìíràn ti mú kúrò lọ́dọ̀ wọn tí wọ́n sì rí ọkàn ìgbàgbọ́ wọn.

  18. Deuteronômio 23

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 23
    Mostrando versículos 2–12 de 25

    2Kí ọmọ àlè má ṣe wọ ìpéjọ Olúwa, pàápàá títí dé ìran kẹwàá.

    11Ṣùgbọ́n nígbà tí ó bá di ìrọ̀lẹ́ o ní láti wẹ ara rẹ, àti ní àṣálẹ́ kí o padà sínú àgọ́.

    12Sàmì sí ibìkan lóde àgọ́, níbi tí o lè máa lọ láti dẹ ara rẹ lára.

  19. 2 Samuel 23

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 23
    Mostrando versículos 27–38 de 39

    27Abieseri ará Anatoti,Sibekai ará Huṣati;

    28Salmoni ará Ahohi,Maharai ará Netofa;

    38Ira ará Itri,Garebu ará Itri.

  20. Provérbios 16

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 16
    Mostrando versículos 8–27 de 33

    8Ó sàn kí ó kéré pẹ̀lú òdodoju èrè púpọ̀ pẹ̀lú èrú lọ.

    18Ìgbéraga ní í ṣáájú ìparun,agídí ọkàn ní í ṣáájú ìṣubú.

    27Ènìyàn búburú ń pèteọ̀rọ̀ rẹ̀ sì dàbí i iná tí ń jóni.

Léxico (correspondência exata) Semântico (correspondência relacionada) Versículos omitidos Contexto do capítulo