Pular para o conteúdo
Publicidade

Esdras 3

Títún pẹpẹ kọ́

1 Nígbà ó di oṣù keje àwọn ọmọ Israẹli ti nínú àwọn ìlú wọn, àwọn ènìyàn péjọpọ̀ gẹ́gẹ́ ẹnìkan Jerusalẹmu. 2 3.2: El 27.1.Nígbà náà ni Jeṣua ọmọ Josadaki àti àwọn àlùfáà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli àti àwọn ènìyàn rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ kọ́ pẹpẹ Ọlọ́run Israẹli láti ẹbọ sísun níbẹ̀, gẹ́gẹ́ ìlànà a ti kọ sínú ìwé òfin Mose ènìyàn Ọlọ́run. 3 ó tilẹ̀ jẹ́ ̀àwọn ènìyàn ó wọn ń wọ́n síbẹ̀, wọ́n kọ́ pẹpẹ sórí ìpìlẹ̀ rẹ̀, wọ́n ẹbọ sísun lórí rẹ̀ Olúwa, ọrẹ àárọ̀ àti ìrọ̀lẹ́. 4 Nígbà náà ìbámu pẹ̀ohun a kọ, wọ́n ṣe àjọ àgọ́ ìpàdé pẹ̀iye ẹbọ sísun a fi lélẹ̀ fún ọjọ́ kọ̀̀kan. 5 Lẹ́yìn náà, wọ́n ṣe ìrúbọ ẹbọ sísun àtìgbàdégbà, ẹbọ oṣù tuntun àti gbogbo àwọn ẹbọ fún gbogbo àpèjẹ a sọ́tọ̀ fún Olúwa, àti àwọn a gẹ́gẹ́ ọrẹ àtinúwá fún Olúwa. 6 ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù keje, wọ́n bẹ̀rẹ̀ ẹbọ sísun Olúwa, ó tilẹ̀ jẹ́ a ì ì fi ìpìlẹ̀ ilé Olúwa lélẹ̀.

Títún tẹmpili kọ́

7 Nígbà náà ni wọ́n fún àwọn ̀mọ̀àti àwọn gbẹ́nàgbẹ́owó, wọ́n tún fi oúnjẹ, ohun mímu àti òróró fún àwọn ará Sidoni àti Tire, wọ́n ba à le è igi kedari gba ti orí omi Òkun láti Lebanoni Joppa, gẹ́gẹ́ Kirusi ọba Persia ti pàṣẹ.

8 oṣù kejì ọdún kejì lẹ́yìn wọ́n ti padà ilé Ọlọ́run Jerusalẹmu, Serubbabeli ọmọ Ṣealitieli, Jeṣua ọmọ Josadaki àti àwọn arákùnrin yòókù (àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi àti gbogbo àwọn ó ti ìgbèkùn Jerusalẹmu) bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ náà. Wọ́n yan àwọn ọmọ Lefi ó ọmọ-ogun ọdún sókè láti máa bojútó kíkọ́ ilé Olúwa. 9 Jeṣua àti àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn arákùnrin rẹ̀ àti Kadmieli àti àwọn ọmọ rẹ̀, àwọn ọmọ Juda (àwọn ìran Hodafiah) àti àwọn ọmọ Henadadi àti àwọn ọmọ wọn àti àwọn arákùnrin wọngbogbo ará Lefiparapọ̀ láti bojútó àwọn òṣìṣẹ́ náà wọ́n ń ṣiṣẹ́ lórí í kíkọ́ ilé Ọlọ́run.

10 Nígbà àwọn ̀mọ̀gbé ìpìlẹ̀ ilé Olúwa kalẹ̀, àwọn àlùfáà nínú aṣọ iṣẹ́ àlùfáà wọn pẹ̀fèrè, àti àwọn ará Lefi (àwọn ọmọ Asafu) pẹ̀símbálì, dúró ipò wọn láti yin Olúwa, Dafidi ọba Israẹli ti fi lélẹ̀. 11 Pẹ̀ìyìn àti ọpẹ́ ni wọ́n kọrin Olúwa:

"Ó dára;

ìfẹ́ rẹ̀ Israẹli dúró títí láé."

Gbogbo àwọn ènìyàn fi ohùn ariwo ńlá yin Olúwa, nítorí a ti fi ìpìlẹ̀ ilé Olúwa lélẹ̀. 12 Ṣùgbọ́n ̀pọ̀ lára àwọn àgbà àlùfáà àti àwọn ará Lefi àti àwọn olórí ìdílé, ó ti tẹmpili Olúwa ti tẹ́lẹ̀, wọ́n sọkún kíkorò nígbà wọ́n ìpìlẹ̀ tẹmpili Olúwa yìí wọ́n fi lélẹ̀, nígbà ̀pọ̀ kígbe fún ayọ̀. 13 ẹni ó le mọ ìyàtọ̀ láàrín igbe ayọ̀ àti ẹkún, nítorí ariwo àwọn ènìyàn náà pọ̀ bẹ́̀ gẹ́́. Wọ́n gbọ́ igbe náà ̀jíjìn réré.

Veja também