Pular para o conteúdo
Publicidade

Ester 2

Esteri di ayaba

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, Ahaswerusi ọba dáwọ́ ìbínú un rẹ̀ dúró, ó rántí i Faṣti àti ohun ó ti ṣe àti àṣẹ ó pa nípa tirẹ̀. 2 Nígbà náà ni ìránṣẹ́ ọba ó ̀dọ̀ rẹ̀ , "Jẹ́ a ọmọbìnrin arẹwà ì ti mọ ọkùnrin fún ọba. 3 Àti ọba ó yan àwọn aláṣẹ gbogbo agbègbè ilẹ̀ ọba láti gbogbo àwọn arẹwà ọmọbìnrin wọ̀nyí jọ ilé àwọn obìnrin ilé ìṣọ́ Susa. a wọn fún ìtọ́Hegai, ìwẹ̀ọba, ẹni ó ṣe olùtọ́àwọn obìnrin; a ṣe ìtọ́u wọn dáradára. 4 Nígbà náà ọmọbìnrin ó tẹ́ ọba lọ́rùn ó jẹ́ ayaba dípò Faṣti." Ìmọ̀ràn yìí tẹ́ ọba lọ́rùn, ó tẹ̀e.

5 Ó ṣe ìgbà náà ará a Júù kan ilé ìṣọ́ ti Susa, ẹni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mordekai ọmọ Jairi, ọmọ Ṣimei, ọmọ Kiṣi, ̀Benjamini, 6 ẹni Nebukadnessari ọba Babeli ti gbé lọ ìgbèkùn láti Jerusalẹmu, lára àwọn wọ́n ìgbèkùn pẹ̀ọba Jekoniah ọba Juda. 7 Mordekai arákùnrin kan ẹni orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Hadassa, ẹni ó tọ́ dàgbà nítorí baba bẹ́̀ ni ìyá. Obìnrin yìí, ẹni a tún mọ̀ Esteri, ó dára ó lẹ́, Mordekai u gẹ́gẹ́ ọmọ rẹ̀ nígbà baba àti ìyá rẹ̀ ti .

8 Nígbà a ti kéde òfin àti àṣẹ ọba, ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọmọbìnrin ni a ilé ti ìṣọ́ Susa, abẹ́ ìtọ́Hegai. A Esteri náà ààfin ọba pẹ̀, a á Hegai lọ́wọ́, ẹni ó jẹ́ alábojútó ilé àwọn obìnrin. 9 Ọmọbìnrin náà ú, ó ojúrere rẹ̀, lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ ó pèsè àwọn ohun ó dára àti oúnjẹ pàtàkì fún un. Ó yan àwọn ìránṣẹ́bìnrin wúńdíá méje láti ààfin ọba òun àti àwọn ìránṣẹ́bìnrin náà lọ ibi ó dára nínú ilé àwọn obìnrin.

10 Esteri ì sọ nípa àwọn ènìyàn àti ìdílé e rẹ̀, nítorí Mordekai ti pàṣẹ fún un ó ṣe sọ ́. 11 ojoojúmọ́ ni Mordekai máa ń rìn iwájú ilé àwọn obìnrin láti wo Esteri ṣe àlàáfíà àti ohun ó ṣẹlẹ̀ i.

12 àkókò fún obìnrin kọ̀̀kan láti lọ ̀dọ̀ ọba Ahaswerusi, ó láti lo ohun èlò ń ara lẹ́a yàn fún àwọn obìnrin fún oṣù méjìlá, yóò lo òróró òjìá fún oṣù mẹ́, yóò lo ohun èlò olóòórùn dídùn tùràrí àti ìpara fún oṣù mẹ́pẹ̀. 13 Báyìí ni yóò ṣe lọ síwájú ọba: ohunkóhun ó béèrè ni wọ́n fi fún un láti inú ilé àwọn obìnrin lọ ààfin ọba. 14 alẹ́ ni yóò lọ síbẹ̀, ó di òwúrọ̀ yóò padà ilé kejì nínú ilé àwọn obìnrin abẹ́ ìtọ́Ṣaaṣigasi ìwẹ̀ọba ẹni ó máa ń ṣe ìtọ́àwọn àlè. Òun lọ ̀dọ̀ ọba mọ́ àyàfi inú ọba dùn i, ó ránṣẹ́ ó orúkọ obìnrin.

15 Nígbà ó kan Esteri (ọmọbìnrin Mordekai gbà ṣe ọmọ, ọmọbìnrin arákùnrin rẹ̀ ó ń jẹ́ Abihaili) láti lọ ̀dọ̀ ọba, wọn béèrè fún ohunkóhun ju èyí Hegai, ìwẹ̀ọba ẹni ó jẹ́ olùtọ́ilé àwọn obìnrin sọ ó ṣe lọ. Esteri ojúrere lọ́dọ̀ gbogbo àwọn ó i. 16 A Esteri lọ síwájú ọba Ahaswerusi ibùgbé ọba oṣù kẹwàá, ó jẹ́ oṣù Tebeti, ọdún keje ìjọba rẹ̀.

17 Esteri wu ọba ju àwọn obìnrin tókù lọ, Ó ojúrere àti oore-ọ̀fẹ́ gbà ju ti àwọn wúńdíá tókù lọ. Nítorí náà ó fi adé ọba e orí ó fi ṣe ayaba dípò Faṣti. 18 Ọba ṣe àsè ńlá, àsè Esteri, fún gbogbo àwọn ọlọ́àti àwọn ìjòyè e rẹ̀. Ó kéde ìsinmi jákèjádò ìgbèríko ó pín ̀bùn fún wọn pẹ̀ọba ṣe lawọ́ .

Mordekai Àṣírí Ìṣọ̀tẹ̀

19 Nígbà àwọn wúńdíá tún péjọ ìgbà kejì, Mordekai jókòó ẹnu-ọ̀ọba. 20 Ṣùgbọ́n Esteri pa àṣírí ìdílé e rẹ̀ àti ibi ó ti mọ́ gẹ́gẹ́ Mordekai ṣe sọ fún un ó ṣe, nítorí ó ń tẹ̀àṣẹ Mordekai fún un gẹ́gẹ́ ó ṣe máa ń ṣe nígbà ó ̀dọ̀ Mordekai.

21 àsìkò Mordekai jókòó ẹnu-ọ̀ọba, Bigitana àti Tereṣi, àwọn ìjòyè ọba méjì wọ́n máa ń ṣọ́ ẹnu-ọ̀, wọ́n bínú, wọ́n ń ̀láti pa ọba Ahaswerusi. 22 Ṣùgbọ́n Mordekai mọ̀ nípa ̀tẹ̀ náà, ó sọ̀ fún ayaba Esteri, Esteri sọ fún ọba, wọ́n fi ọlá fún Mordekai. 23 Nígbà wọ́n wádìí ̀rọ̀ náà ó jásí òtítọ́, a so àwọn ìjòyè méjèèjì náà kọ́. Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni a kọ sínú ìwé ìtàn iwájú ọba.

Veja também