Publicidade

Provérbios 8

Ọgbọ́n n fi ìpè síta

1 Ǹjẹ́ ọgbọ́n ha ń kígbe síta?

Òye ha ń gbé ohùn rẹ sókè?

2 ibi gíga ̀gbẹ́ ̀,

ìkóríta, ó dúró;

3 ẹgbẹ́ ibodè ó wọ ìlú,

ẹnu ibodè ni ó ń kígbe sókè:

4 "i yín ̀yin ènìyàn, mo ń kígbe ;

mo gbé ohun mi sókè gbogbo ènìyàn.

5 ̀yin aláìmọ̀kan, kọ́gbọ́n;

̀yin aṣiwèrè, gba òye.

6 gbọ́, nítorí èmi ó sọ̀rọ̀ ohun iyebíye;

Èmí ṣí ètè mi láti sọ ohun ó tọ́,

7 ẹnu mi ń sọ ohun í ṣe òtítọ́,

nítorí ètè mi kórìíra ibi.

8 Gbogbo ̀rọ̀ ẹnu mi ni ó tọ́,

èyí ó jẹ́ ̀tàn tàbí àyídáyidà níbẹ̀.

9 Fún olóye gbogbo rẹ̀ ni ó tọ̀;

wọ́n jẹ́ aláìlẹ́gàn fún gbogbo ẹni ó ìmọ̀.

10 Yan ̀kọ́ mi dípò fàdákà,

ìmọ̀ dípò o wúrà àṣàyàn,

11 nítorí ọgbọ́n ṣe iyebíye iyùn lọ,

ohun ọkàn rẹ̀ fẹ́ a le fiwé e.

12 "Èmi, ọgbọ́n ń gbé pẹ̀òye;

mo ìmọ̀ àti ọgbọ́n-inú.

13 Ìbẹ̀Olúwa ni ìkórìíra ibi

mo kórìíra ìgbéraga àti agídí,

ìwà ibi àti ̀rọ̀ ̀tàn.

14 Ìmọ̀ràn àti ọgbọ́n ó kooro jẹ́ tèmi

mo òye àti agbára.

15 Nípasẹ̀ mi ni ọba ń ṣàkóso

àwọn aláṣẹ ń ṣe òfin ó dára.

16 Nípasẹ̀ mi àwọn ọmọ-aládé ń ṣàkóso,

àti gbogbo ọlọ́ń ṣàkóso ilẹ̀ ayé.

17 Mo fẹ́ràn àwọn ó fẹ́ràn mi,

àwọn ó mi mi.

18 Lọ́dọ̀ mi ni ọrọ̀ àti ọlá ,

ọrọ̀ í tọ́jọ́ àti ìgbéga rere.

19 Èso mi dára ju wúrà dáradára lọ;

ohun ń ju àṣàyàn fàdákà lọ.

20 ń rìn ̀òdodo,

ojú ̀òtítọ́,

21 ń fi ọrọ̀ fún gbogbo àwọn ó fẹ́ràn mi

mo ń ilé ìṣúra wọn kún.

22 "Èmi ni Olúwa kọ́kọ́ nínú iṣẹ́ rẹ̀.

Ṣáájú àwọn iṣẹ́ rẹ̀ àtijọ́;

23 a ti yàn láti ayérayé,

láti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀, ayé bẹ̀rẹ̀.

24 Nígbà ì Òkun, ni a ti mi,

nígbà ì ìsun ó omi nínú;

25 a fi àwọn òkè ipò wọn,

ṣáájú àwọn òkè ni a ti mi,

26 ó ilẹ̀ ayé tàbí àwọn oko rẹ̀

tàbí èyíkéyìí nínú eruku ayé.

27 Mo níbẹ̀ nígbà ó fi àwọn ̀run ipò wọn,

nígbà ó fi òsùwọ̀n àyíká sórí ibú omi,

28 nígbà ó ṣẹ̀òfúrufú lókè

ó fi orísun ibú omi ipò rẹ̀ láì le è yẹsẹ̀,

29 nígbà ó ṣe ààlà fún omi Òkun

omi ba à kọjá ààlà àṣẹ rẹ̀,

àti nígbà ó pààlà ìpìlẹ̀ ayé.

30 Nígbà náà èmi ni gbẹ́nàgbẹ́̀gbẹ́ rẹ̀

mo kún fún inú dídùn lójoojúmọ́,

mo ń yọ̀ nígbà gbogbo níwájú rẹ̀.

31 Mo ń yọ̀ nínú gbogbo àgbáyé ó

mo inú dídùn àwọn ọmọ ènìyàn.

32 "Nítorí náà báyìí, ̀yin ọmọ mi,

ìbùkún ni fún àwọn ó pa ̀mi mọ́.

33 Fetí ìtọ́sọ́mi o gbọ́n;

ṣe pa á sápá kan.

34 Ìbùkún ni fún ẹni ó fetísílẹ̀ mi,

ń ṣọ́ẹnu-ọ̀mi lójoojúmọ́,

ń dúró ẹnu-ọ̀mi.

35 Nítorí ẹnikẹ́ni ó mi ìyè

ó ojúrere gbà lọ́dọ̀ Olúwa.

36 Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ó kọ̀ láti ń pa ara rẹ̀ lára

gbogbo ẹni ó kórìíra mi fẹ́ ikú."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-