Pular para o conteúdo
Publicidade

Zacarias 14

Olúwa Wa Jọba

1 Kíyèsi i, ọjọ́ Olúwa ń bọ̀, a ó pín ìkógun rẹ̀ láàrín rẹ̀.

2 Nítorí èmi ó gbogbo orílẹ̀-èdè jọ Jerusalẹmu fún ogun; a ó ko ìlú náà, a ó àwọn ilé, a ó ba àwọn obìnrin jẹ́, ààbọ̀ ìlú náà yóò lọ ìgbèkùn, a yóò ìyókù àwọn ènìyàn náà kúrò ni ìlú náà. 3 Nígbà náà ni Olúwa yóò jáde lọ, yóò àwọn orílẹ̀-èdè náà , gẹ́gẹ́ í ti ìjà ọjọ́ ogun. 4 Ẹsẹ̀ rẹ̀ yóò dúró ni ọjọ́ náà lórí òkè Olifi, ó níwájú Jerusalẹmu ni ìlà-oòrùn, òkè Olifi yóò á méjì, ìhà ìlà-oòrùn àti ìhà ìwọ̀-oòrùn, àfonífojì ńlá ńlá yóò : ìdajì òkè náà yóò ṣí síhà àríwá, àti ìdajì rẹ̀ síhà gúúsù. 5 ̀yin ó àfonífojì àwọn òkè mi, nítorí àfonífojì òkè náà yóò Aseli: nítòótọ́, ̀yin ó fún ìmìmì-ilẹ̀ ni ọjọ́ Ussiah ọba Juda: Olúwa Ọlọ́run mi yóò , àti gbogbo àwọn Ẹni mímọ́ pẹ̀rẹ̀.

6 Yóò ṣe ni ọjọ́ náà, ìmọ́lẹ̀ yóò mọ́, bẹ́̀ ni yóò ṣókùnkùn. 7 Ṣùgbọ́n yóò jẹ́ ọjọ́ kan mímọ́ fún Olúwa, í ṣe ̀sán, í ṣe òru; ṣùgbọ́n yóò ṣe , ni àṣálẹ́ ìmọ́lẹ̀ yóò .

8 Yóò ṣe ọjọ́ náà, omi ìyè yóò Jerusalẹmu sàn lọ; ìdajì wọn síhà Òkun ìlà-oòrùn, àti ìdajì wọn síhà okùn ̀yìn: nígbà ̀rùn àti nígbà òtútù ni yóò bẹ́̀.

9 Olúwa yóò jẹ ọba lórí gbogbo ayé; ni ọjọ́ náà ni Olúwa kan yóò wa orúkọ rẹ̀ nìkan náà ni orúkọ.

10 A ó gbogbo ilẹ̀ padà bi pẹ̀tẹ́lẹ̀ kan láti Geba Rimoni lápá gúúsù Jerusalẹmu: yóò di aginjù, ṣùgbọ́n a ó gbé Jerusalẹmu sókè, yóò gbe ipò rẹ̀, láti ibodè Benjamini títí ibi ibodè èkínní, ibodè igun , àti láti ilé ìṣọ́ Hananeli ibi ìfúntí wáìnì ọba. 11 14.11: If 22.3.Ènìyàn yóò máa gbé ibẹ̀, yóò ìparun mọ́; ṣùgbọ́n a ó máa gbé Jerusalẹmu láìléwu.

12 Èyí ni yóò jẹ́ ààrùn Olúwa yóò fi kọlu gbogbo àwọn ènìyàn ti ó ba Jerusalẹmu ; ẹran-ara wọn yóò nígbà wọn dúró ni ẹsẹ̀ wọn, ojú wọn yóò ni ihò wọn, ahọ́n wọn yóò bàjẹ́ ni ẹnu wọn. 13 Yóò ṣe ni ọjọ́ náà, ìrọ́kẹ̀kẹ̀ ńlá láti ̀dọ̀ Olúwa yóò láàrín wọn; wọn ó di ọwọ́ ara wọn , ọwọ́ èkínní yóò dìde ọwọ́ èkejì rẹ̀. 14 Juda pẹ̀yóò ni Jerusalẹmu: ọrọ̀ gbogbo àwọn kèfèrí ó káàkiri ni a ó kójọ, wúrà àti fàdákà, àti aṣọ, ̀pọ̀lọpọ̀. 15 Bẹ́̀ ni ààrùn ẹṣin, ìbáaka, ìbákasẹ, àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, yóò , àti gbogbo ẹranko ń bẹ nínú àgọ́.

16 Yóò ṣe, olúkúlùkù ẹni o nínú gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ó dìde Jerusalẹmu yóò máa gòkè lọ lọ́dọọdún láti sìn ọba, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, àti láti ṣe àjọyọ̀ àsè àgọ́ náà. 17 Yóò ṣe, ẹnikẹ́ni yóò gòkè nínú gbogbo ìdílé ayé Jerusalẹmu láti sín ọba, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, òjò yóò rọ̀ fún wọn. 18 14.18-19: Isa 19; Jr 46; El 29–32.ìdílé Ejibiti gòkè lọ, wọn , fi ara wọn hàn wọn òjò; ààrùn náà yóò , Olúwa yóò fi kọlù àwọn kèfèrí gòkè láti ṣe àjọyọ̀ àsè àgọ́ náà. 19 Èyí ni yóò jẹ́ ìyà Ejibiti, àti ìyà gbogbo orílẹ̀-èdè gòkè láti pa àsè àgọ́ mọ́.

20 ọjọ́ náà ni "mímọ́ Olúwa" yóò lára ṣaworo ẹṣin: àti àwọn ìkòkò ni ilé Olúwa yóò dàbí àwọn ọpọ́n ń bẹ níwájú pẹpẹ. 21 Nítòótọ́, gbogbo ìkòkò ni Jerusalẹmu àti ni Juda yóò jẹ́ mímọ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun: àti gbogbo àwọn ń ẹbọ yóò , wọn ó ìkòkò díẹ̀, wọn ó bọ ẹran wọn nínú rẹ̀, ni ọjọ́ náà ni àwọn Kenaani mọ́ ni ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun.

Veja também