Publicidade

Bíblia

Por Bíblia Online

A Bíblia é a Palavra de Deus — viva, eficaz e mais cortante que espada de dois gumes. Toda Escritura é inspirada por Deus e útil para ensinar, repreender, corrigir e instruir em justiça.

Inspiração divina

Toda Escritura é inspirada por Deus. Homens santos falaram da parte de Deus movidos pelo Espírito Santo.

Gbogbo ìwé mímọ́ ni ó ìmísí Ọlọ́run ó èrè fún ̀kọ́, fún ìbániwí, fún ìtọ́ni, fún ìkọ́ni ó nínú òdodo. ènìyàn Ọlọ́run , a ti múra sílẹ̀ pátápátá fun iṣẹ́ rere gbogbo.

Àti láti ìgbà ọmọdé ni ìwọ ti mọ Ìwé Mímọ́, ó sọ ́ di ọlọ́gbọ́n ìgbàlà nípasẹ̀ ìgbàgbọ́ nínú Kristi Jesu. Gbogbo ìwé mímọ́ ni ó ìmísí Ọlọ́run ó èrè fún ̀kọ́, fún ìbániwí, fún ìtọ́ni, fún ìkọ́ni ó nínú òdodo. ènìyàn Ọlọ́run , a ti múra sílẹ̀ pátápátá fun iṣẹ́ rere gbogbo.

Ju gbogbo rẹ̀ lọ, òye yìí àsọtẹ́lẹ̀ ìwé mímọ́ kankan ó wáyé nípa ìtumọ̀ wòlíì fún rara rẹ̀. Nítorí àsọtẹ́lẹ̀ kan ti ipá ìfẹ́ ènìyàn ; ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn ń sọ̀rọ̀ láti ̀dọ̀ Ọlọ́run a ti ń darí wọn láti ọwọ́ ̀Mímọ́ .

Ṣaápọn láti fi ara rẹ̀ hàn níwájú Ọlọ́run bi ẹni ó yege àti òṣìṣẹ́ láti tijú, ó ń pín ̀rọ̀ òtítọ́ ó ti yẹ.

Wàásù ̀rọ̀ náà, ṣe àìsimi àkókò ó wọ̀, àti àkókò ti wọ̀; ni , ṣe ìtọ́ni, gbani níyànjú pẹ̀ìpamọ́ra àti ̀kọ́ gbogbo.

Títí èmi ó fi , máa fiyèsí kíkàwé àti ìgbaniníyànjú àti ìkọ́ni.

Poder da Palavra

A Palavra de Deus é viva e eficaz. O céu e a terra passarão, mas as minhas palavras jamais passarão.

Nítorí ̀rọ̀ Ọlọ́run , ó agbára, ó mu ju idàkídà olójú méjì lọ, ó ń gún ni, àní títí pínpín ọkàn àti ̀, àti oríkèé àti ̀inú egungun, òun ni olùmọ̀ èrò inú àti ète ọkàn.

̀run àti ayé yóò rékọjá, ṣùgbọ́n ̀rọ̀ mi yóò rékọjá.

Ṣùgbọ́n Jesu dáhùn , "A ti kọ ìwé rẹ̀ : Ènìyàn yóò láààyè nípa àkàrà nìkan, ṣe nípa gbogbo ̀rọ̀ ti ó ti ẹnu Ọlọ́run jáde .’ "

Gẹ́gẹ́ òjò àti yìnyín

ti wálẹ̀ láti ̀run

í padà ibẹ̀

láì bomirin ilẹ̀

ó ó tanná ó rudi,

bẹ́̀ yóò fi irúgbìn fún afúnrúgbìn

àti àkàrà fún ̀jẹun,

bẹ́̀ ni ̀rọ̀ mi ó jáde láti ẹnu mi ;

yóò padà sọ́dọ̀ mi lọ́wọ́ òfo,

ṣùgbọ́n yóò ṣe ohun mo fẹ́,

yóò ète mi mo fi rán an ìmúṣẹ.

Sọ wọ́n di mímọ́ nínú òtítọ́, òtítọ́ ni ̀rọ̀ rẹ.

̀yin ń ìwé mímọ́ nítorí ̀yin nínú wọn ni ̀yin ìyè nípẹ̀kun. Wọ̀nyí ni àwọn ó ń jẹ́rìí mi.

ṣùgbọ́n ̀rọ̀ Olúwa dúró títí láé."

̀rọ̀ náà yìí ni ìyìnrere a wàásù fún yín.

Báwo ni àwọn ̀dọ́ yóò ti ṣe pa ̀rẹ̀ mọ́?

Láti máa gbé ìbámu ̀rọ̀ rẹ.

Òtítọ́ ni gbogbo ̀rọ̀ rẹ;

gbogbo òfin òdodo rẹ láéláé ni.

Estudar e pregar

Os bereanos examinavam as Escrituras diariamente. Procura apresentar-te a Deus aprovado como obreiro que maneja bem a Palavra.

Àwọn Júù Berea ìyìn ju àwọn Tẹsalonika lọ, wọn fi tọkàntọkàn gbà ̀rọ̀ náà. Wọ́n ń inú ìwé mímọ́ lójoojúmọ́ nǹkan wọ̀nyí bẹ́̀.

Àti Paulu, gẹ́gẹ́ ìṣe rẹ̀, ó wọlé tọ̀ wọ́n lọ, ni ọjọ́ ìsinmi mẹ́ta ó ń wọn fi ̀rọ̀ ̀rọ̀ nínú ìwé mímọ́. Ó ń túmọ̀, ó ń fihàn , Kristi ṣàìmá jìyà, o jíǹde kúrò nínú òkú; àti , "Jesu yìí ẹni èmi ń wàásù fún yin, òun ni Kristi náà."

Filipi si súré lọ, ó gbọ́ ti ó ń ka ìwé wòlíì Isaiah, Filipi i , "Ohun ìwọ ń yìí ha ?"

Ó dáhùn , "Yóò ha ṣe mi, ṣe ẹnìkan tọ́ ̀?" Ó bẹ Filipi ó gòkè , ó òun jókòó.

Ibi ìwé mímọ́ ìwẹ̀náà ń náà ni èyí:

"A á àgùntàn lọ fún pípa;

àti ̀dọ́-àgùntàn ń dákẹ́ níwájú olùrẹ́run rẹ̀,

bẹ́̀ gẹ́gẹ́ ni ohun kan.

Filipi ya ẹnu rẹ̀, bẹ̀rẹ̀ láti ibi ìwé mímọ́ yìí, ó wàásù ìyìnrere ti Jesu fún un.

Esra ti fi ara rẹ̀ fún kíkọ́ àti pípa òfin Olúwa mọ́, ó ń kọ́ òfin àti ìlànà Mose Israẹli.

Ó fún wọn , "̀yin òye , yigbì àyà láti gba gbogbo èyí àwọn wòlíì ti gbọ́, ha yẹ Kristi ó jìyà nǹkan wọ̀nyí ó wọ inú ògo rẹ̀ lọ." Ó bẹ̀rẹ̀ láti Mose àti gbogbo àwọn wòlíì , ó túmọ̀ nǹkan fún wọn nínú ìwé mímọ́ gbogbo nípa ti ara rẹ̀.

Nígbà náà ni Jesu fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ , "Gbogbo agbára ni ̀run àti ayé ni a ti fi fún mi. Nítorí náà, lọ, sọ wọ́n di ọmọ-ẹ̀yìn orílẹ̀-èdè gbogbo, máa bamitiisi wọn orúkọ Baba àti ti Ọmọ àti ti ̀Mímọ́. kọ́ wọn láti máa kíyèsi ohun gbogbo èyí mo ti pàṣẹ fún yín. Nítorí èmi pẹ̀yín ìgbà gbogbo títí ó fi òpin ayé."

̀yin ti ń lọ, máa wàásù yìí , Ìjọba ̀run dẹ̀dẹ̀.’

Revelação e fidelidade

A Palavra do Senhor veio aos profetas. A graça de Deus se manifestou na Escritura para a salvação de todos.

̀rọ̀ Olúwa tọ̀ ́ ,

̀rọ̀ Olúwa ó tọ Joẹli ọmọ Petueli .

̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah :

̀rọ̀-ìjìnlẹ̀: ̀rọ̀ Olúwa Israẹli láti ẹnu Malaki.

̀rọ̀ Olúwa tọ Sekariah , ,

Lẹ́yìn náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ Isaiah ,

Ọdún ojúrere Olúwa

̀Olúwa Olódùmarè lára mi

nítorí Olúwa ti fi àmì òróró yàn

láti wàásù ìyìnrere fún àwọn tálákà.

Ó ti rán mi láti ṣe àwòtán oníròbìnújẹ́

láti kéde ìdásílẹ̀ fún àwọn ìgbèkùn

àti ìtúsílẹ̀ kúrò nínú òkùnkùn fún àwọn ẹlẹ́wọ̀n,

láti kéde ọdún ojúrere Olúwa

àti ọjọ́ ̀san ti Ọlọ́run wa,

láti tu àwọn ń ṣọ̀fọ̀ nínú,

àti láti pèsè fún àwọn inú wọn bàjẹ́ Sioni

láti wọn ládé ẹwà dípò eérú,

òróró ayọ̀ dípò ̀fọ̀,

àti aṣọ ìyìn dípò ìpòrúru ọkàn.

A ó wọ́n igi óákù òdodo,

irúgbìn Olúwa

láti fi ọláńlá rẹ̀ hàn.

Viver pela Palavra

Não só de pão vive o homem. Nada acrescentes nem diminuas. A Palavra é alimento, guia e espada do cristão.

"Gbogbo ̀rọ̀ Ọlọ́run jẹ́ aláìlábùkù;

òun ni ààbò fún gbogbo ẹni fi í ṣe ibi ìpamọ́ wọn.

ṣe fi kún ̀rọ̀ rẹ̀,

àìṣe bẹ́̀ yóò yóò sọ ́ di òpùrọ́.

Èmi kìlọ̀ fún olúkúlùkù ẹni ń gbọ́ ̀rọ̀ ìsọtẹ́lẹ̀ inú ìwé yìí , ẹnikẹ́ni ba fi kún wọn, Ọlọ́run yóò fi kún àwọn ìyọnu a kọ sínú ìwé yìí fún un. ẹnikẹ́ni kúrò nínú ̀rọ̀ ìwé ìsọtẹ́lẹ̀ yìí, Ọlọ́run yóò ipa tirẹ̀ kúrò nínú ìwé ìyè, àti kúrò nínú ìlú mímọ́ náà, àti kúrò nínú àwọn ohun a kọ sínú ìwé yìí.

ìyìnrere mìíràn

Ó mi lẹ́nu tètè yapa kúrò lọ́dọ̀ ẹni ó yín sínú oore-ọ̀fẹ́ Kristi, ìyìnrere mìíràn. Nítòótọ́, ìyìnrere mìíràn ó tilẹ̀ ṣe àwọn kan , ń yọ yín lẹ́nu, wọ́n ń fẹ́ ìyìnrere Kristi padà. Ṣùgbọ́n ó ṣe àwa ni tàbí angẹli kan láti ̀run , ni ó wàásù ìyìnrere mìíràn fún yín ju èyí a wàásù rẹ̀ fún yín lọ, jẹ́ ó di ẹni ìfibú títí láéláé! àwa ti ṣáájú, bẹ́̀ ni mo tún nísinsin yìí , ẹnìkan wàásù ìyìnrere mìíràn fún yín ju èyí ̀yin gbà lọ, jẹ́ ó di ẹni ìfibú títí láéláé!

máa á , sùúrù Olúwa wa ìgbàlà ni; Paulu pẹ̀arákùnrin wa olùfẹ́, ti kọ̀yín gẹ́gẹ́ ọgbọ́n a fi fún un. ó ń sọ̀rọ̀ nǹkan wọ̀nyí pẹ̀nínú ìwé rẹ̀ gbogbo nínú èyí ti ohun mìíràn sọ̀rọ̀ láti ni gbé , èyí ti àwọn òpè àti àwọn aláìdúró níbìkan ń lo, wọ́n ti ń lo ìwé mímọ́ ìyókù, ìparun ara wọn.

Nítorí ohun gbogbo a kọ tẹ́lẹ̀, ni a kọ láti fi kọ́ wa , nípa sùúrù àti ìtùnú ìwé mímọ́, àwa ìrètí.

Ǹjẹ́ wọn ó ha ti ṣe pe ẹni wọn gbàgbọ́? Wọn ó ha ti ṣe gba ẹni wọn gbúròó rẹ̀ gbọ́? Wọn o ha ti ṣe gbọ́ láìsí oníwàásù? Wọ́n ó ha ti ṣe wàásù, ṣe a rán wọn? Gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ , "Ẹsẹ̀ àwọn ń wàásù ìyìnrere àlàáfíà ti dára , àwọn ń wàásù ìròyìn ayọ̀ ohun rere!"

Ṣùgbọ́n í ṣe gbogbo wọn ni ó gbọ́ ti ìyìnrere. Nítorí Isaiah , "Olúwa, ta ni ó gba ìyìn wa gbọ́?" Ǹjẹ́ nípa gbígbọ́ ni ìgbàgbọ́ ti í , àti gbígbọ́ nípa ̀rọ̀ Ọlọ́run.

Èmi tijú ìyìnrere Jesu, nítorí agbára Ọlọ́run ín ṣe láti gba gbogbo àwọn ó gbàgbọ́ , ̀rọ̀ yìí ni a kọ́kọ́ wàásù àwọn Júù nìkan, ṣùgbọ́n nísinsin yìí fún àwọn Helleni pẹ̀. Nítorí nínú ìyìnrere ni òdodo Ọlọ́run ti farahàn, òdodo Ọlọ́run nípa ìgbàgbọ́ láti ìbẹ̀rẹ̀ òpin gẹ́gẹ́ a ti kọ ́ nínú Ìwé Mímọ́ , "Olódodo yóò nípa ìgbàgbọ́ rẹ̀."

Àwa gbà ̀ti ayé yìí, ṣe ̀ẹni ó ti ̀dọ̀ Ọlọ́run wa, a òye ohun Ọlọ́run fi fún wa lọ́fẹ̀́. Èyí ni àwa ń , í ṣe èyí a ń kọ nípa ̀rọ̀ ọgbọ́n ènìyàn, ṣùgbọ́n èyí ̀Mímọ́ fi ń kọ ènìyàn, èyí a ń fi ohun ̀ohun ̀. Ṣùgbọ́n ènìyàn nípa ti ara gba ohun ti ̀Ọlọ́run wọ̀n-ọn-nì, nítorí wèrè ni wọ́n jásí fún un, òun le mọ̀ wọ́n, nítorí nípa ̀a fi ń wádìí wọn.

Nítorí , nínú ọgbọ́n Ọlọ́run, ayé le mọ̀ òun nípa ọgbọ́n àti ìṣeféfé wọn. Ó gba gbogbo àwọn ó gbàgbọ́ nípa ìwàásù àwọn aráyé òmùgọ̀ àti ̀rọ̀ yẹ̀yẹ́.

Nítorí àwọn Júù ń béèrè àmì, àwọn Helleni ń ṣàfẹ́ọgbọ́n, ṣùgbọ́n àwa ń wàásù Kristi ti a kàn mọ́ àgbélébùú, òkúta ìkọ̀sẹ̀ àwọn Júù àti òmùgọ̀ fún àwọn kèfèrí. Ṣùgbọ́n àwọn Ọlọ́run , àti àwọn Júù àti àwọn Giriki, Kristi ni agbára Ọlọ́run, àti ọgbọ́n Ọlọ́run.

Nítorí Kristi rán mi láti máa ṣe ìtẹ̀bọmi, ṣùgbọ́n ó rán mi láti máa wàásù ìyìnrere: í ṣe nípa ọgbọ́n ènìyàn, a máa ṣe sọ àgbélébùú Kristi aláìlágbára.

Ṣùgbọ́n ̀yin ni ìran a yàn olú àlùfáà, Orílẹ̀-èdè mímọ́, ènìyàn ̀tọ̀ ki ̀yin fi ọláńlá ẹni ó yín jáde kúrò nínú òkùnkùn sínú ìmọ́lẹ̀ ìyanu rẹ̀ hàn.

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-