Publicidade

1 Reis 17

Elijah kéde ̀

1 Elijah ará Tiṣibi láti Tiṣbi Gileadi fún Ahabu , "Olúwa Ọlọ́run Israẹli ti , ẹni èmi ń sìn, yóò ìrì tàbí òjò ọdún díẹ̀ ń bọ̀ ṣe nípa ̀rọ̀ mi."

2 Nígbà náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ Elijah , 3 "Kúrò níhìn-ín, kọjú ìhà ìlà-oòrùn, o fi ara rẹ pamọ́ níbi odò Keriti, ń bẹ níwájú Jordani. 4 Ìwọ yóò mu nínú odò náà, mo ti pàṣẹ fún àwọn ẹyẹ ìwò láti máa bọ́ níbẹ̀."

5 Bẹ́̀ ni ó ṣe gẹ́gẹ́ Olúwa ti sọ fún un. Ó lọ ̀odò Keriti, ń bẹ níwájú Jordani, ó dúró síbẹ̀. 6 Àwọn ẹyẹ ìwò àkàrà àti ẹran fún un òwúrọ̀, àti àkàrà àti ẹran alẹ́, ó ń mu nínú odò náà.

Elijah àti opó Sarefati

7 Ó ṣe lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀, odò náà gbẹ nítorí òjò ilẹ̀ náà. 8 ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ ́ , 9 "Lọ nísinsin yìí Sarefati ti Sidoni, o dúró síbẹ̀. Èmi ti pàṣẹ fún obìnrin opó kan níbẹ̀ láti máa bọ́ ." 10 Bẹ́̀ ni ó lọ Sarefati. Nígbà ó ibodè ìlú náà, obìnrin opó kan ń ṣa igi jọ níbẹ̀. Ó i, ó béèrè , "Ǹjẹ́ o bu omi díẹ̀ fún mi nínú ohun èlò èmi ó mu?" 11 ó ti ń lọ ú , ó i , "Jọ̀ ́, òkèlè oúnjẹ díẹ̀ fún mi lọ́wọ́ rẹ."

12 Obìnrin opó náà a lóhùn , "Olúwa Ọlọ́run rẹ ti , èmi àkàrà, ṣe ìkúnwọ́ ìyẹ̀fun nínú ìkòkò àti òróró díẹ̀ nínú kólòbó. Èmi ń ṣa igi díẹ̀ jọ láti lọ ilé, èmi ó pèsè rẹ̀ fún mi àti fún ọmọ mi, àwa jẹ ́: a ."

13 Elijah fún un , "ṣe bẹ̀. Lọ, o ṣe gẹ́gẹ́ o ti . Ṣùgbọ́n kọ́kọ́ ṣe àkàrà kékeré kan fún mi nínú rẹ̀ , o fún mi , lẹ́yìn náà, o ṣe tìrẹ àti ti ọmọ rẹ. 14 Nítorí báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli : Ìkòkò ìyẹ̀fun náà yóò ṣófo, bẹ́̀ ni kólòbó òróró náà yóò gbẹ, títí di ọjọ́ Olúwa yóò rọ òjò orí ilẹ̀.’ "

15 Ó lọ, ó ṣe gẹ́gẹ́ Elijah ti sọ fún un. Oúnjẹ fún Elijah àti obìnrin náà àti ilé rẹ̀ ojoojúmọ́. 16 Nítorí ìkòkò ìyẹ̀fun náà ṣófo, kólòbó òróró náà gbẹ, gẹ́gẹ́ ̀rọ̀ Olúwa ó ti ipa Elijah sọ.

17 Ó ṣe lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, ọmọ obìnrin ó ni ilé náà ṣe àìsàn, àìsàn náà le bẹ́̀, ó fi . 18 Obìnrin náà fún Elijah , "lo mi, ènìyàn Ọlọ́run? Ìwọ ha tọ̀ láti ̀ṣẹ̀ mi ìrántí, àti láti pa ọmọ?"

19 Elijah fún un , "Gbé ọmọ rẹ fún mi." Ó yọ ́ jáde àyà rẹ̀, ó gbé e lọ iyàrá òkè ilé níbi òun ń gbé, ó tẹ́ orí ibùsùn tirẹ̀. 20 Nígbà náà ni ó pe Olúwa , "Olúwa Ọlọ́run mi, ìwọ ha ibi opó náà pẹ̀lọ́dọ̀ ẹni èmi ń ṣe àtìpó, nípa pípa ọmọ rẹ̀?" 21 Nígbà náà ni ó na ara rẹ̀ lórí ọmọdé náà ̀̀mẹta, ó pe Olúwa , "Olúwa Ọlọ́run mi, jẹ́ ̀ọmọdé yìí ó tún padà tọ̀ ́ !"

22 Olúwa gbọ́ igbe Elijah, ̀ọmọdé náà tún padà tọ̀ ́ , ó sọjí. 23 Elijah ọmọdé náà, ó gbé e sọ̀kalẹ̀ láti inú yàrá òkè náà sínú ilé. Ó fi ìyá rẹ̀ lọ́wọ́; Elijah , "ó, ọmọ rẹ !"

24 Obìnrin náà fún Elijah , "Nísinsin yìí mo mọ̀ ènìyàn Ọlọ́run ni ìwọ ń ṣe, àti òtítọ́ ni ̀rọ̀ Olúwa ẹnu rẹ."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-