Publicidade

Isaías 38

Àìsàn Hesekiah

1 ọjọ́ náà ni Hesekiah ṣe àìsàn ojú ikú. Wòlíì Isaiah ọmọ Amosi lọ ̀dọ̀ rẹ̀, ó , "Ohun Olúwa nìyìí: Palẹ̀ ilé è rẹ mọ́, ó ti yẹ nítorí ìwọ yóò ; ìwọ yóò dìde àìsàn yìí."

2 Hesekiah ojú u rẹ̀ ara ògiri, ó gba àdúrà Olúwa, 3 "Rántí, Ìwọ Olúwa, mo ti rìn pẹ̀òtítọ́ níwájú rẹ, àti mo ti fi ọkàn dídúró ṣinṣin ṣe ohun ó dára ojú ù rẹ." Bẹ́̀ ni Hesekiah sọkún kíkorò.

4 Lẹ́yìn náà ni ̀rọ̀ Olúwa tọ Isaiah , 5 "Lọ o sọ fún Hesekiah , Ohun Olúwa nìyìí, Ọlọ́run Dafidi baba rẹ sọ , Èmi ti gbọ́ àdúrà rẹ mo ti omijé rẹ, Èmi yóò fi ọdún mẹ́̀́dógún kún ọjọ́ ayé rẹ. 6 Èmi yóò gba ìwọ àti ìlú yìí sílẹ̀ kúrò lọ́wọ́ ọba Asiria. Èmi yóò dáàbò bo ìlú yìí.

7 " Èyí yìí ni àmì Olúwa fún láti fihàn Olúwa yóò ìpinnu rẹ̀ ṣẹ. 8 Èmi yóò òjìji oòrùn ó padà sẹ́yìn ìṣísẹ̀ mẹ́wàá nínú èyí ó fi sọ̀kalẹ̀ ibi àtẹ̀gùn ti Ahasi.’ " Bẹ́̀ ni oòrùn padà sẹ́yìn ìṣísẹ̀ mẹ́wàá ibi ó ti tẹ́lẹ̀.

9 Ìwé Hesekiah ọba Juda kọ lẹ́yìn àìsàn rẹ̀ nígbà ó ti gbádùn tán.

10 Èmi , "àárín gbùngbùn ọjọ́ ayé mi

èmi ó ha kọjá lọ ibodè ikú

a dùn àwọn ọdún mi ó ṣẹ́?"

11 Èmi , "Èmi yóò tún Olúwa mọ́,

àní Olúwa, ilẹ̀ àwọn alààyè;

èmi yóò síjú wo ọmọ ènìyàn mọ́,

tàbí n pẹ̀àwọn ó ń

gbe orílẹ̀ ayé báyìí.

12 Gẹ́gẹ́ àgọ́ olùṣọ́-àgùntàn,

ilé mi ni a ti lulẹ̀ a gbà kúrò lọ́wọ́ mi.

Gẹ́gẹ́ ahunṣọ mo ti ayé mi nílẹ̀,

bẹ́̀ ni òun ti mi kúrò lára àṣà;

̀sán àti òru ni ìwọ ṣe òpin mi.

13 Èmi fi sùúrù dúró títí di àfẹ̀mọ́júmọ́,

ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ kìnnìún ó ti fọ́ gbogbo egungun mi;

̀sán àti òru ni ìwọ fi ṣe òpin mi.

14 Èmi dún gẹ́gẹ́ àkọ̀ tàbí alápáǹdẹ̀dẹ̀,

èmi káàánú gẹ́gẹ́ aṣọ̀fọ̀ àdàbà.

Ojú mi rẹ̀wẹ̀gẹ́gẹ́ mo ti ń wo àwọn ̀run.

Ìdààmú mi, Ìwọ Olúwa, fún ìrànlọ́wọ́ mi!"

15 Ṣùgbọ́n ni èmi sọ?

Òun ti mi sọ̀rọ̀ àti òun

tìkára rẹ̀ ti ṣe èyí.

Èmi yóò máa rìn ìrẹ̀lẹ̀ gbogbo ọjọ́ mi

nítorí ìpọ́njú ̀mi yìí.

16 Olúwa, nípa nǹkan báwọ̀nyí ni àwọn ènìyàn ń gbé;

àti ̀mi iyè nínú wọn pẹ̀.

Ìwọ ìlera mi padà

o jẹ́ n láààyè.

17 Nítòótọ́ fún àlàáfíà ara mi ni,

ti mo ìkorò ńlá.

Nínú ìfẹ́ rẹ ìwọ pa mọ́,

kúrò nínú ̀gbun ìparun;

ìwọ ti fi gbogbo ̀ṣẹ̀ mi ̀yìn rẹ.

18 Nítorí isà òkú le è yìn ́,

ipò òkú le è kọ orin ìyìn rẹ;

àwọn ó sọ̀kalẹ̀ sínú ̀gbun

ìrètí fún òtítọ́ rẹ.

19 Alààyè, àwọn alààyè wọ́n ń yìn ́,

gẹ́gẹ́ èmi ti ń ṣe lónìí;

àwọn baba sọ fún àwọn ọmọ wọn nípa òtítọ́ rẹ.

20 Olúwa yóò gbà

bẹ́̀ ni àwa yóò kọrin pẹ̀ohun èlò olókùn

gbogbo ọjọ́ ayé wa

nínú tẹmpili ti Olúwa.

21 Isaiah ti sọ , "Pèsè ìṣù ̀pọ̀tọ́ (ohun gbígbóná a mọ́ ojú egbò) o fi ojú oówo náà, òun yóò gbádùn."

22 Hesekiah béèrè , "ni yóò jẹ́ àmì èmi yóò gòkè lọ tẹmpili Olúwa?"

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-