Publicidade

Esdras 7

Esra Jerusalẹmu

1 Lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí, àkókò ìjọba ọba Artasasta Persia, Esra ọmọ Seraiah, ọmọ Asariah, ọmọ Hilkiah, 2 ọmọ Ṣallumu, ọmọ Sadoku, ọmọ Ahitubu, 3 ọmọ Amariah, ọmọ Asariah, ọmọ Meraioti, 4 ọmọ Serahiah, ọmọ Ussi, ọmọ Bukki, 5 ọmọ Abiṣua, ọmọ Finehasi, ọmọ Eleasari, ọmọ Aaroni olórí àlùfáà6 Esra yìí gòkè láti Babeli. Olùkọ́ ó ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ nípa òfin Mose, èyí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, ti fi fún wọn. Ọba fi gbogbo ohun ó béèrè fún un, nítorí ọwọ́ Olúwa Ọlọ́run lára rẹ̀. 7 ọdún keje ọba Artasasta díẹ̀ lára àwọn ọmọ Israẹli, àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, àwọn akọrin, àwọn aṣọ́àti àwọn ń ṣiṣẹ́ nínú tẹmpili náà gòkè Jerusalẹmu.

8 oṣù karùn-ún ọdún keje ọba yìí ni Esra Jerusalẹmu. 9 Ó bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò rẹ̀ láti Babeli ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kìn-ín-ní, ó Jerusalẹmu ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù karùn-ún nítorí ọwọ́ àánú Ọlọ́run rẹ̀ ara rẹ̀. 10 Esra ti fi ara rẹ̀ fún kíkọ́ àti pípa òfin Olúwa mọ́, ó ń kọ́ òfin àti ìlànà Mose Israẹli.

Ọba Artasasta kọ lẹ́Esra

11 Èyí ni ̀lẹ́ti ọba Artasasta fún àlùfáà Esra olùkọ́ni, ẹni ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ nínú àkọsílẹ̀ òfin àti ìlànà Olúwa fún Israẹli.

12 Artasasta, ọba àwọn ọba.

àlùfáà Esra, olùkọ́ òfin Ọlọ́run ̀run.

Àlàáfíà.

13 Mo pàṣẹ ẹnikẹ́ni nínú àwọn ọmọ Israẹli, àwọn àlùfáà àti àwọn Lefi, ti ó abẹ́ ìṣàkóso ìjọba mi, ó fẹ́ láti lọ Jerusalẹmu tẹ̀lọ. 14 Ọba àti àwọn ìgbìmọ̀ rẹ̀ méjèèje rán lọ láti wádìí nípa òfin Ọlọ́run rẹ ó ọwọ́ rẹ nípa Juda àti Jerusalẹmu. 15 Síwájú i, ìwọ ó fàdákà àti wúrà lọ pẹ̀rẹ èyí ọba àti àwọn ìgbìmọ̀ rẹ fi tọkàntọkàn fún Ọlọ́run Israẹli, ẹni ibùjókòó rẹ̀ Jerusalẹmu, 16 pẹ̀gbogbo fàdákà àti wúrà ìwọ agbègbè ìjọba Babeli àti àwọn ọrẹ àtinúwá àwọn ènìyàn àti ti àwọn àlùfáà fún tẹmpili Ọlọ́run wọn Jerusalẹmu. 17 Pẹ̀owó yìí, i dájú ó ra àwọn akọ màlúù, àwọn àgbò àti akọ ̀dọ́-àgùntàn, pẹ̀ọrẹ ohun jíjẹ, àti ọrẹ ohun mímu, ìwọ ó fi wọ́n ẹbọ lórí pẹpẹ tẹmpili Ọlọ́run rẹ Jerusalẹmu.

18 Ìwọ àti àwọn Júù arákùnrin rẹ fi èyí tókù fàdákà àti wúrà ṣe ohunkóhun ó dára lójú yín, ìbámu pẹ̀ìfẹ́ Ọlọ́run yín. 19 gbogbo ohun èlò a fi ìkáwọ́ rẹ fún Ọlọ́run Jerusalẹmu fún ìsìn nínú tẹmpili Ọlọ́run rẹ. 20 Ohunkóhun mìíràn o nílò fún tẹmpili Ọlọ́run rẹ ó láti pèsè, o u láti inú ìṣúra ọba.

21 Èmi, ọba Artasasta, pàṣẹ fún gbogbo olùtọ́ilé ìṣúra agbègbè Eufurate láìrójú láti pèsè ohunkóhun àlùfáà Esra, olùkọ́ni òfin Ọlọ́run ̀run béèrè lọ́wọ́ yín 22 ọgọ́rùn-ún kan tálẹ́ǹtì fàdákà, ọgọ́rùn-ún kan òsùwọ̀n àlìkámà, àti ọgọ́rùn-ún bati ọtí wáìnì, àti ọgọ́rùn-ún bati òróró olifi, àti ̀pọ̀lọpọ̀ iyọ̀. 23 Ohunkóhun Ọlọ́run ̀run fẹ́, jẹ́ ó di ṣíṣe pípé fún tẹmpili Ọlọ́run ̀run. Èéṣe ìbínú yóò ṣe agbègbè ọba àti orí àwọn ọmọ rẹ̀? 24 Ìwọ láti mọ̀ ìwọ àṣẹ láti sọ sísan owó orí, owó òde tàbí owó bodè di dandan fún àwọn àlùfáà, àwọn Lefi, àwọn akọrin, àwọn aṣọ́, àwọn òṣìṣẹ́ tẹmpili tàbí àwọn òṣìṣẹ́ mìíràn nínú ilé Ọlọ́run yìí.

25 Ìwọ Esra, ìbámu pẹ̀ọgbọ́n Ọlọ́run rẹ̀, èyí ó , yan àwọn adájọ́ àgbà àti àwọn onídàájọ́ láti máa ṣe ìdájọ́ fún àwọn ènìyàn agbègbè Eufurate, gbogbo àwọn ó mọ òfin Ọlọ́run rẹ. Ìwọ yóò kọ́ ẹnikẹ́ni mọ̀ àwọn òfin náà. 26 Ẹnikẹ́ni ṣe ìgbọ́ràn òfin Ọlọ́run rẹ àti òfin ọba ó gbọdọ̀ tàbí a e jáde tàbí a gbẹ́sẹ̀ ẹrù rẹ̀ tàbí a sọ ́ sínú ̀wọ̀n.

27 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wa, ẹni ó fi ọkàn ọba láti ọlá ilé Olúwa Jerusalẹmu ̀yìí. 28 Ẹni ó jẹ́ ojúrere rẹ̀ tàn kàn níwájú ọba àti àwọn olùbádámọ̀ràn àti iwájú àwọn alágbára ìjòyè ọba. Nítorí ọwọ́ Olúwa Ọlọ́run lára mi, mo ọkàn le, mo àwọn olórí jọ láàrín àwọn ènìyàn Israẹli láti gòkè lọ pẹ̀mi.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-