Publicidade

Jeremias 33

Ìlérí ìmúpadàbọ̀sípò

1 Nígbà Jeremiah nínú àgbàlá túbú, ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ ́ lẹ́̀kejì: 2 "Èyí ni ohun Olúwa sọ, ẹni ó ayé, Olúwa ó mọ ayé ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀, Olúwa ni orúkọ rẹ̀: 3 , èmi ó lóhùn, èmi ó sọ ohun alágbára ńlá àti ̀pọ̀ ohun ṣe é wádìí ìwọ mọ̀ fún .4 Nítorí èyí ni ohun Olúwa Ọlọ́run àwọn Israẹli sọ nípa àwọn ilẹ̀ ìlú yìí àti ààfin àwọn ọba Juda ó ti lulẹ̀ nítorí àwọn ìdọ̀àti idà 5 nínú ìjà pẹ̀Kaldea: Wọn yóò kún fún ̀pọ̀ òkú ọmọkùnrin èmi yóò pa nínú ìbínú àti nínú ìrunú mi. Èmi ó pa ojú mi mọ́ kúrò ìlú yìí nítorí gbogbo búburú wọn.

6 " ó, èmi ó ̀àti oògùn ìmúláradá í; èmi ó wo àwọn ènìyàn mi sàn. Èmi ó jẹ́ wọn ó jẹ ìgbádùn lọ́pọ̀lọ́pọ̀ àlàáfíà àti òtítọ́. 7 Èmi ó Juda àti Israẹli kúrò nínú ìgbèkùn, èmi ó tún wọn kọ́ gẹ́gẹ́ wọ́n ṣe tẹ́lẹ̀. 8 Èmi ó wẹ̀ wọ́n kúrò nínú gbogbo ̀ṣẹ̀ wọ́n ti ṣẹ mi. Èmi ó dárí gbogbo ̀ṣẹ̀ àìṣedéédéé wọn mi wọ́n. 9 Nígbà náà ni ìlú yìí ó fún mi òkìkí, ayọ̀, ìyìn àti ọlá níwájú gbogbo orílẹ̀-èdè ayé; wọ́n gbọ́ gbogbo rere èmi ṣe fún wọn. Wọn ó bẹ̀, wọn ó wárìrì fún ̀pọ̀lọpọ̀ oore àti àlàáfíà èmi pèsè fún wọn.

10 "Èyí ni ohun Olúwa , ̀yin yóò nípa ibí yìí , "Ó dahoro, láìsí ènìyàn tàbí ẹran." Síbẹ̀ ìlú Juda àti òpópónà Jerusalẹmu ó dahoro, láìsí ẹni gbé ibẹ̀; ìbá à se ènìyàn tàbí ẹran, yóò gbọ́ lẹ́̀kan . 11 Ariwo ayọ̀ àti inú dídùn, ohùn ìyàwó àti ti ọkọ ìyàwó àti ohùn àwọn ó ru ẹbọ ọpẹ́ wọn nílé Olúwa :

" ‘ "Yin Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

nítorí Olúwa dára,

ìfẹ́ rẹ̀ dúró títí láéláé."

Nítorí èmi ó ìkólọ ilẹ̀ náà padà o ṣe tẹ́lẹ̀,’ ni Olúwa .

12 "Èyí ni ohun Olúwa àwọn ọmọ-ogun , ilẹ̀ yìí ó ti dahoro láìsí ọkùnrin àti àwọn ẹran nínú gbogbo ìlú, pápá oko fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn láti àwọn ẹran ̀sìn wọn sinmi. 13 ìlú òkè wọ̀n-ọn-nì, nínú ìlú àfonífojì, àti nínú ìlú ìhà gúúsù, àti ilẹ̀ ti Benjamini, ibi wọ̀n-ọn-nì ó Jerusalẹmu , àti ìlú Juda ni agbo àgùntàn yóò tún máa kọjá ọwọ́ ẹni ń wọ́n,ni Olúwa .

14 " Àwọn ọjọ́ náà ń bọ̀,’ ni Olúwa , èmi ó ìlérí rere mo ṣe fún ilé Israẹli àti ilé Juda ṣẹ.

15 " ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àti àkókò náà,

Èmi ó gbé olódodo dìde láti ̀ka Dafidi.

Yóò ṣe ìdájọ́ àti ohun ó tọ́ ilẹ̀ náà.

16 ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, Juda yóò di ẹni ìgbàlà.

Jerusalẹmu yóò máa gbé láìséwu.

Orúkọ yìí ni a ó máa é

Olúwa wa olódodo.

17 Nítorí báyìí ni Olúwa : Dafidi kùnà láti ọkùnrin yóò jókòó lórí ìtẹ́ ilé Israẹli. 18 Bẹ́̀ ni àwọn àlùfáà ó jẹ́ ọmọ Lefi kùnà láti ọkùnrin kan ó dúró níwájú mi gbogbo ìgbà láti ẹbọ sísun; ẹbọ jíjẹ àti láti pèsè ìrúbọ.’ "

19 ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah : 20 "Èyí ni ohun Olúwa sọ: ìwọ májẹ̀mi òru bẹ́̀ ̀sán àti òru àkókò wọn mọ́. 21 Nígbà náà ni májẹ̀mi pẹ̀Dafidi ìránṣẹ́ mi àti májẹ̀mi pẹ̀Lefi ó jẹ́ àlùfáà, àwọn ìránṣẹ́ níwájú mi bàjẹ́, Dafidi ẹni láti jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀. 22 Èmi ó àwọn ọmọ lẹ́yìn Dafidi ìránṣẹ́ mi àti Lefi ó jẹ́ oníwàásù níwájú mi di ìràwọ̀ ojú ̀run, ṣe é àti iyẹ̀pẹ̀ ojú Òkun ṣe é wọ́n.’ "

23 ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah : 24 "Ǹjẹ́ ìwọ kíyèsi àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń sọ : Olúwa ti kọ àwọn ọba méjèèjì ó yàn sílẹ̀’? Nítorí náà, ni wọ́n ti ṣe kẹ́gàn àwọn ènìyàn mi. Wọn mọ̀ wọ́n gẹ́gẹ́ orílẹ̀-èdè kan. 25 Báyìí ni Olúwa : èmi ti da májẹ̀mi pẹ̀̀sán àti òru àti pẹ̀òfin ̀run àti ayé yẹ̀. 26 Nígbà náà ni èmi ó kọ ọmọ lẹ́yìn Jakọbu àti Dafidi ìránṣẹ́ mi èmi yan ̀kan nínú ọmọkùnrin rẹ̀ láti jẹ́ alákòóso lórí àwọn ọmọ Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu; nítorí èmi ó ìkólọ wọn padà; èmi ó ṣàánú fún wọn.’ "

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-