Publicidade

Fim do mundo

Por Bíblia Online

A Bíblia fala sobre o fim do mundo como evento certo e definitivo. Céus e terra passarão, mas as palavras de Jesus jamais passarão. A questão não é se, mas quando.

Os céus passarão

Os céus e a terra passarão, mas as palavras de Jesus permanecerão para sempre. O mundo presente é temporário.

̀run àti ayé yóò rékọjá, ṣùgbọ́n ̀rọ̀ mi yóò rékọjá.

"Lójúkan náà, lẹ́yìn ìpọ́njú ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì,

" ni oòrùn yóò ṣókùnkùn,

òṣùpá yóò fi ìmọ́lẹ̀ rẹ hàn;

àwọn ìràwọ̀ ojú ̀run yóò sílẹ̀,

agbára ojú ̀run ni a ó tìtì.

A mọ ọjọ́ tàbí wákàtí náà

"Ṣùgbọ́n ẹnìkan ti ó mọ ọjọ́ àti wákàtí òpin náà yóò , àwọn angẹli ̀run pàápàá mọ̀ ́n. Àní, ọmọ mọ̀ ́n, ṣe Baba mi nìkan ṣoṣo mọ̀ ́n.

Ọjọ́ àti wákàtí a mọ̀

"Ṣùgbọ́n ẹni ó mọ ọjọ́ tàbí wákàtí nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹlẹ̀. Àwọn angẹli ̀run pàápàá mọ̀. Àní, èmi pẹ̀mọ̀ ́n, ṣe baba nìkan.

O dia do Senhor

O dia do Senhor virá como ladrão. Os céus passarão com grande estrondo, e os elementos se dissolverão no fogo.

Ṣùgbọ́n ọjọ́ Olúwa ń bọ̀ olè òru; nínú èyí àwọn ̀run yóò kọjá lọ pẹ̀ariwo ńlá, àti àwọn ìmọ́lẹ̀ ojú ̀run yóò ti inú ooru gbígbóná gidigidi di yíyọ́, ayé àti àwọn iṣẹ́ ó nínú rẹ̀ yóò jóná túútúú.

Ṣùgbọ́n àwọn ̀run àti ayé, ó ń bẹ nísinsin yìí, nípa ̀rọ̀ kan náà ni ó ti jọ ìṣúra fún iná, a pa wọ́n mọ́ de ọjọ́ ìdájọ́ àti ìparun àwọn aláìwà-bí-Ọlọ́run.

Ǹjẹ́ gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò ti yọ́ bẹ́̀, irú ènìyàn wo ni ̀yin ìbá jẹ́ nínú ìwà mímọ́ gbogbo àti ìwà-bí-Ọlọ́run. máa retí, máa múra gírí de dídé ọjọ́ Ọlọ́run, nítorí èyí àwọn ̀run yóò gbiná, wọn yóò di yíyọ́, àwọn ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ yóò ti inú ooru gbígbóná gidigidi di yíyọ́.

Nísinsin yìí, ará, a nílò láti kọ ìwé i yín mọ́ nípa àkókò àti ìgbà, nítorí ̀yin pàápàá mọ̀ ọjọ́ Olúwa yóò olè lóru. àkókò gan an àwọn ènìyàn yóò máa , "Àlàáfíà àti ààbò," nígbà náà ni ìparun òjijì yóò sórí wọn gẹ́gẹ́ ìrọbí obìnrin ó lóyún, wọn ni ibi ààbò láti .

Ṣùgbọ́n ̀yin ará, nínú òkùnkùn nípa nǹkan wọ̀nyí ọjọ́ Olúwa yóò fi yín olè. Nítorí gbogbo yín ni ọmọ ìmọ́lẹ̀ àti ọmọ ̀sán gangan. í ṣe òru tàbí òkùnkùn mọ́.

Ṣùgbọ́n ̀yin ará, nínú òkùnkùn nípa nǹkan wọ̀nyí ọjọ́ Olúwa yóò fi yín olè. Nítorí gbogbo yín ni ọmọ ìmọ́lẹ̀ àti ọmọ ̀sán gangan. í ṣe òru tàbí òkùnkùn mọ́. Nítorí náà, kíyèsára yín ṣe sùn àwọn ẹlòmíràn. máa ṣọ́máa pa ara yín mọ́. Nítorí àwọn wọ́n ń sùn, a máa sùn òru, àwọn ẹni ń mu àmupara, a máa un òru. Ṣùgbọ́n àwa jẹ́ ti ìmọ́lẹ̀, jẹ́ a pa ara wa mọ́, gbígbé ìgbàgbọ́ wọ̀ àti ìfẹ́ ìgbàyà ni òru àti ìrètí ìgbàlà àṣíborí. Nítorí , Ọlọ́run yàn wa láti da ìbínú rẹ̀ gbígbóná orí wa, ṣùgbọ́n ó yàn láti gbà nípasẹ̀ Olúwa wa, Jesu Kristi.

Destruição e renovação

O Dia do Senhor trará juízo sobre os ímpios, mas também novos céus e nova terra onde habita a justiça.

Ọjọ́ ńlá Olúwa

"Ọjọ́ ńlá Olúwa dẹ̀dẹ̀,

ó dẹ̀dẹ̀ ó ń yára bọ̀ kánkán.

tẹ́sílẹ̀, ohùn ẹkún àwọn alágbára;

ọjọ́ Olúwa yóò korò púpọ̀,

ọjọ́ náà yóò jẹ́ ọjọ́ ìbínú,

ọjọ́ ìrora àti ìpọ́njú,

ọjọ́ òfò àti idà ọjọ́ ìdahoro

ọjọ́ òkùnkùn àti ìtẹ̀ba,

ọjọ́ kurukuru àti òkùnkùn biribiri,

ọjọ́ ìpè àti ìpè ogun

àwọn ìlú olódi

àti àwọn ilé ìṣọ́ gíga.

"Èmi yóò ìpọ́njú sórí ènìyàn,

wọn yóò máa rìn gẹ́gẹ́ afọ́,

nítorí àwọn ti dẹ́ṣẹ̀ Olúwa.

̀jẹ̀ wọn ni a ó jáde eruku

àti ẹran-ara wọn ìgbẹ́.

Bẹ́̀ ni fàdákà tàbí wúrà wọn

yóò le gbà wọ́n

ọjọ́ ìbínú Olúwa."

Ṣùgbọ́n gbogbo ayé ni a ó fi iná

ìjowú rẹ̀ parun,

nítorí òun yóò fi ìyára fi òpin

gbogbo àwọn ń gbé ilẹ̀ ayé.

Kíyèsi i, ọjọ́ Olúwa ń bọ̀

ọjọ́ búburú, pẹ̀ìbínú àti ìrunú gbígbóná

láti sọ ilẹ̀ náà dahoro,

àti láti pa àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ inú rẹ̀ run.

Nígbà ó ṣí èdìdì kẹfà mo i, kíyèsi i, ìṣẹ̀lẹ̀ ńlá kan ṣẹ̀; oòrùn dúdú aṣọ ̀fọ̀ onírun, òṣùpá dàbí ̀jẹ̀; àwọn ìràwọ̀ ojú ̀run ṣubú sílẹ̀ gẹ́gẹ́ igi ̀pọ̀tọ́ ń rẹ̀ àìgbó èso rẹ̀ dànù, nígbà ̀fúùfù ńlá í.

A dragoni ńlá náà jáde, ejò láéláé , a ń ni Èṣù, àti Satani, ń tan gbogbo ayé jẹ: a e ilẹ̀ ayé, a àwọn angẹli rẹ̀ jáde pẹ̀rẹ̀.

"Àmì yóò oorun, àti òṣùpá, àti ìràwọ̀; àti lórí ilẹ̀ ayé ìdààmú fún àwọn orílẹ̀-èdè nínú ìpayà híhó Òkun àti ìgbì omi. Àyà àwọn ènìyàn yóò máa fún ìbẹ̀, àti ìrètí nǹkan wọ̀nyí ń bọ̀ sórí ayé: nítorí àwọn agbára ̀run ni a ó tìtì.

Ǹjẹ́ máa ṣọ́, máa gbàdúrà nígbà gbogbo, ba à la gbogbo nǹkan wọ̀nyí yóò ṣẹlẹ̀, dúró níwájú Ọmọ Ènìyàn."

Jerusalẹmu tuntun

Mo ̀run tuntun kan àti ayé tuntun kan, nítorí ̀run ti ìṣáájú àti ayé ìṣáájú ti kọjá lọ; Òkun ṣí mọ́. Mo ìlú mímọ́, Jerusalẹmu tuntun ń ti ̀run sọ̀kalẹ̀ láti ̀dọ̀ Ọlọ́run, a ti múra sílẹ̀ ìyàwó a ṣe lọ́ṣọ̀́ fún ọkọ rẹ̀. Mo gbọ́ ohùn ńlá kan láti orí ìtẹ́ náà , ń , "Kíyèsi i, àgọ́ Ọlọ́run pẹ̀àwọn ènìyàn, òun ó máa wọn gbé, wọn ó máa jẹ́ ènìyàn rẹ̀, àti Ọlọ́run tìkára rẹ̀ yóò pẹ̀wọn, yóò máa jẹ́ Ọlọ́run wọn. Ọlọ́run yóò nu omijé gbogbo kúrò ni ojú wọn; yóò ṣí ikú mọ́, tàbí ̀fọ̀, tàbí ẹkún, bẹ́̀ ni yóò ìrora mọ́, nítorí ohun àtijọ́ kọjá lọ."

Ẹni ó jókòó lórí ìtẹ́ náà, , "Kíyèsi i, mo sọ ohun gbogbo di ̀tun!" Ó fún mi , "Kọ̀rẹ̀, nítorí ̀rọ̀ wọ̀nyí òdodo àti òtítọ́ ni wọ́n."

Seja o primeiro
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-