Publicidade

Isaías 13

Àsọtẹ́lẹ̀ lòdì Babeli

1 13.1–14.23: Isa 47; Jr 50–51; Hk 1–2. ̀rọ̀-ìmọ̀ ó kan Babeli èyí Isaiah ọmọ Amosi .

2 Gbé àsíá sókè orí òkè gbẹrẹfu,

kígbe wọn,

wọ́n

láti wọlé ẹnu-ọ̀àwọn ọlọ́.

3 Mo ti pàṣẹ fún àwọn ẹni mímọ́ mi,

mo ti pe àwọn jagunjagun mi

láti gbé ìbínú mi jáde

àwọn ń yọ̀ nínú ìṣẹ́gun mi.

4 Gbọ́ ohùn kan àwọn orí òkè,

gẹ́gẹ́ i ti ogunlọ́gọ̀ ènìyàn.

Gbọ́ ìdàrúdàpọ̀ láàrín àwọn ìjọba,

gẹ́gẹ́ i ti ìkórajọ àwọn orílẹ̀-èdè!

Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti ogun rẹ̀ jọ

àwọn jagunjagun fún ogun.

5 Wọ́n láti ̀jíjìn réré,

láti ìpẹ̀kun ̀run

Olúwa pẹ̀àwọn ohun ìjà ìbínú rẹ̀,

láti pa gbogbo orílẹ̀-èdè náà run.

6 hu, nítorí ọjọ́ Olúwa súnmọ́ tòsí,

yóò gẹ́gẹ́ ìparun láti ̀dọ̀ Alágbára jùlọ.

7 Nítorí èyí, gbogbo ọwọ́ ni yóò rọ,

ọkàn ẹnìkọ̀̀kan yóò rẹ̀wẹ̀.

8 ̀yóò gbá wọn ,

ìrora àti ìpayínkeke yóò dìwọ́n ,

wọn yóò kérora gẹ́gẹ́ obìnrin ó ń rọbí.

Ẹnìkínní yóò wo ẹnìkejì rẹ̀ pẹ̀ìpayà

ojú wọn á gbinájẹ.

9 Kíyèsi i, ọjọ́ Olúwa ń bọ̀

ọjọ́ búburú, pẹ̀ìbínú àti ìrunú gbígbóná

láti sọ ilẹ̀ náà dahoro,

àti láti pa àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ inú rẹ̀ run.

10 13.10: Mt 24.29; Mk 13.24; If 6.12; 8.12. Àwọn ìràwọ̀ ojú ̀run àti ìkójọpọ̀ wọn

fi ìmọ́lẹ̀ wọn hàn.

Àṣẹ̀ṣẹ̀yọ oòrùn yóò di òkùnkùn

àti òṣùpá fi ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ hàn.

11 Èmi yóò jẹ ayé ìyà nítorí ibi rẹ̀,

àwọn ìkà nítorí ̀ṣẹ̀ wọn.

Èmi yóò fi òpin gààrù àwọn agbéraga

èmi ó rẹ ìgbéraga àwọn aláìláàánú sílẹ̀.

12 Èmi yóò jẹ́ ọkùnrin ó wọn

ju ojúlówó wúrà lọ,

yóò ṣọ̀wọ́n ju wúrà Ofiri lọ.

13 Nítorí náà èmi yóò jẹ́ àwọn ̀run ó wárìrì;

ayé yóò tìtì ibùjókòó rẹ̀

láti ọwọ́ ìbínú Olúwa àwọn ọmọ-ogun,

ọjọ́ ìbínú gbígbóná rẹ.

14 Gẹ́gẹ́ egbin à ń dọdẹ rẹ̀,

gẹ́gẹ́ àgùntàn olùṣọ́,

̀kọ̀̀kan yóò padà tọ àwọn ènìyàn rẹ̀ lọ,

̀kọ̀̀kan yóò padà ilẹ̀ abínibí i rẹ̀.

15 Ẹnikẹ́ni a gbámú ni a ó wọ́ nílẹ̀ tuurutu,

gbogbo àwọn ọwọ́ tẹ̀ ni yóò ti ipa idà .

16 Àwọn ̀dọ́mọdé wọn ni a ó fọ́ wẹ́wẹ́ níṣojú wọn,

gbogbo ilẹ̀ wọn ni a ó

àwọn aya wọn ni a ó dàpọ̀.

17 Kíyèsi i, èmi yóò ru àwọn Media sókè wọn,

àwọn bìkítà fún fàdákà

inú dídùn wúrà.

18 Ọrùn wọn yóò àwọn ̀dọ́mọkùnrin lulẹ̀;

wọn ṣàánú àwọn ̀dọ́mọdé

tàbí wọn síjú àánú wo àwọn ọmọdé.

19 Babeli, ohun ̀ṣọ́ àwọn ìjọba

ògo ìgbéraga àwọn ará Babeli

ni Ọlọ́run yóò da ojú rẹ̀ bolẹ̀

gẹ́gẹ́ Sodomu àti Gomorra.

20 A yóò tẹ̀ ibẹ̀ mọ́

tàbí á gbé inú rẹ̀ láti ìrandíran;

ará Arabia yóò pa àgọ́ níbẹ̀ mọ́,

olùṣọ́-àgùntàn kan yóò ẹran rẹ̀ sinmi níbẹ̀.

21 13.21: If 18.2. Ṣùgbọ́n àwọn ẹranko igbó ni yóò dùbúlẹ̀ níbẹ̀,

àwọn ajáko yóò kún inú ilé wọn,

níbẹ̀ ni àwọn òwìwí yóò máa gbé

níbẹ̀ ni àwọn ewúrẹ́ igbó yóò ti máa bẹ́ kiri.

22 Ìkookò yóò máa gbó ibùba wọn,

àwọn ajáko nínú arẹwà ààfin wọn.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-