Pular para o conteúdo
Publicidade

Resultados da busca por "fé"

260 resultados encontrados

  1. Jeremias 48

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 48
    Mostrando versículos 6–36 de 47

    6Sá! Àsálà fún ẹ̀mí yín;kí ẹ sì dàbí aláìní ní aginjù.

    22sórí Diboni, Nebo àti Beti-Diblataimu,

    23sórí Kiriataimu, Beti-Gamu àti Beti-Meoni,

    36"Nítorí náà ọkàn mi ró fún Moabu bí rè,ọkàn mi ró bí rè fún àwọn ọkùnrin Kiri-Hareseti.Nítorí ìṣúra tí ó kójọ ṣègbé.

  2. Êxodo 15

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 15
    Mostrando versículos 3–14 de 27

    3Ológun ni Olúwa,Olúwa ni orúkọ rẹ,

    4kẹ̀kẹ́ ogun Farao àti ogun rẹ̀ni ó mú wọ inú Òkun.Àwọn ọmọ-ogun Farao tó jáfáfá jùlọni ó rì sínú Òkun Pupa.

    14Orílẹ̀-èdè yóò gbọ́ wọn yóò wárìrì.Ìkáàánú yóò mi àwọn ènìyàn Filistia.

  3. Ezequiel 13

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 13
    Mostrando versículos 1–17 de 23

    1Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:

    4Israẹli àwọn wòlíì rẹ dàbí kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ nínú pápá.

    17"Nísinsin yìí, ọmọ ènìyàn, dojúkọ àwọn ọmọbìnrin ènìyàn rẹ tí wọ́n ń sọtẹ́lẹ̀ láti inú èrò ọkàn wọn, sọtẹ́lẹ̀ sí wọn

  4. Deuteronômio 9

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 9
    Mostrando versículos 8–24 de 29

    89.8-21: El 32.7-20.Ní Horebu ẹ̀yin ti mú kí Olúwa bínú, títí dé bi pé ó fẹ́ run yín.

    22Ẹ̀yin tún mú Olúwa bínú ní Tabera, Massa àti ní Kibirotu-Hattaafa.

    24Láti ìgbà tí mo ti mọ̀ yín ni ẹ ti ń ṣọ̀tẹ̀ sí Olúwa.

  5. Salmos 39

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 39
    Mostrando versículos 5–10 de 13

    5Ìwọ ti ṣe ayé mibí ìbú àtẹ́lẹwọ́,ọjọ́ orí mi sì dàbí asánní iwájú rẹ.Dájúdájú olúkúlùkù ènìyàn nínúìjókòó rere rẹ̀ jásí asán pátápátá. Sela.

    8Gbà mí lọ́wọ́ ìrékọjá mi gbogbo.Kí o má sì sọ mí di ẹni ẹ̀gànàwọn ènìyàn búburú.

    10Mú pàṣán rẹ kúrò ní ara mi;èmí ṣègbé tán nípa lílù ọwọ́ rẹ.

  6. Atos 7

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 7
    Mostrando versículos 21–51 de 60

    217.21: Ek 2.5-6,10.Nígbà tí wọn sí gbe é sọnù, ọmọbìnrin Farao gbé e, ó sì tọ ọ́ dàgbà gẹ́gẹ́ bí ọmọ ara rẹ̀.

    22A sì kọ́ Mose ni gbogbo ọgbọ́n ara Ejibiti, ó sì pọ̀ ni ọ̀rọ̀ àti ní ìṣe.

    51 7.51: Ek 33.3,5; Jr 9.26; 6.10; Nu 27.14; Isa 63.10. "Ẹ̀yin ọlọ́rùn líle àti aláìkọlà àyà àti etí! Bí àwọn baba yín gẹ́lẹ́ ni ẹ̀yin rí. Nígbà gbogbo ni ẹ̀yin máa ń dènà Ẹ̀mí Mímọ́!

  7. Provérbios 17

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 17
    Mostrando versículos 4–28 de 28

    4Ènìyàn búburú ń tẹ́tí sí ètè tí ń sọ ibi;òpùrọ́ a máa fetí sí ahọ́n búburú.

    18Ènìyàn aláìgbọ́n ṣe ìbúra,ó sì ṣe onídùúró fún aládùúgbò rẹ̀.

    26Kò dára láti fìyà jẹ ènìyàn tí kò ṣẹ̀,tàbí láti na ìjòyè lórí òtítọ́ inú wọn.

    28Kódà aláìgbọ́n máa ń dàbí ọlọ́gbọ́n bí ó bá dákẹ́,àti bí olóye bí ó bá tèmétè.

  8. Jeremias 19

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 19
    Mostrando versículos 1–12 de 15

    1Èyí ní ohun tí Olúwa wí: "Lọ ra ìkòkò lọ́dọ̀ alámọ̀, mú dání lára àwọn àgbàgbà ọkùnrin àti wòlíì.

    2Kí o sì lọ sí àfonífojì ọmọ Beni-Hinnomu, níwájú ẹnu ibodè Harsiti, níbẹ̀ ni kí o sì kéde gbogbo ọ̀rọ̀ tí èmi yóò sọ fún ọ.

    12Èyí ni ohun tí èmi yóò ṣe sí ibí yìí àti àwọn tí ń gbé ní ibí yìí ni Olúwa wí. Èmi yóò mú ìlú yìí dàbí Tofeti.

  9. Êxodo 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 4–14 de 22

    4Nígbà tí Olúwa rí i pe Mose ti lọ láti lọ wò ó, Ọlọ́run ké pè é láti àárín igbó náà, "Mose! Mose!"Mose sì dáhùn ó wí pé, "Èmi nìyìí."

    11Ṣùgbọ́n Mose wí fún Ọlọ́run pé, "Ta ni èmi, tí èmi yóò tọ Farao lọ, ti èmi yóò sì kó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti?"

    14Ọlọ́run sì sọ fún Mose pé, "èmi ni ti ń jẹ́ èmi ni. Èyí ni ìwọ yóò sọ fún àwọn ará Israẹli: ‘èmi ni ni ó rán mi sí i yín.’ "

  10. Ezequiel 44

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 44
    Mostrando versículos 5–26 de 31

    5Olúwa sì sọ fún mì pé, "Ọmọ ènìyàn, wò dáradára, fetísílẹ̀ dáradára kí o sì fiyèsí ohun gbogbo tí mo sọ fún ọ nípa òfin lórí ilé Olúwa náà. Fiyèsí ẹnu-ọ̀nà ilé Ọlọ́run náà àti gbogbo àbájáde ibi mímọ́.

    21Àlùfáà kankan kò gbọdọ̀ mu ọtí nígbà tí ó bá wọ àgbàlá tí inú.

    26Lẹ́yìn ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀, ki òun kí ó dúró fún ọjọ́ méje.

  11. Deuteronômio 32

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 32
    Mostrando versículos 38–48 de 52

    38ọlọ́run tí ó jẹ ọ̀rá ẹran ẹbọ wọntí ó ti mu ọtí i wáìnì ẹbọ ohun mímu wọn?Jẹ́ kí wọn dìde láti gbà wọ́n!Jẹ́ kí wọn ṣe ààbò fún un yín!

    39"Wò ó báyìí pé, Èmi fúnra à mi, Èmi ni!Kò sí ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn mi.Mo sọ di kíkú mo sì tún sọ di ààyè.Mo ti ṣá lọ́gbẹ́ Èmi yóò sì mu jiná,kò sí ẹni tí ó lè gbà kúrò lọ́wọ́ ọ̀ mi.

    48Ní ọjọ́ kan náà, Olúwa sọ fún Mose pé,

  12. Salmos 19

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 19
    Mostrando versículos 7–12 de 14

    7Pípé ni òfin Olúwa,ó ń yí ọkàn padà.Ẹ̀rí Olúwa dánilójú,ó sọ òpè di ọlọ́gbọ́n.

    9Ìbẹ̀rù Olúwa mọ́,ó ń faradà títí láéláé.Ìdájọ́ Olúwa dájúòdodo ni gbogbo wọn.

    12Ta ni ó lè mọ àṣìṣe rẹ̀?Dáríjì mí nínú àṣìṣe mi tí ó pamọ́.

  13. Provérbios 25

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 25
    Mostrando versículos 4–28 de 28

    4Mú ìdàrọ́ kúrò lára fàdákàohun èlò yóò sì jáde fún alágbẹ̀dẹ fàdákà.

    19Bí eyín tí ó bàjẹ́ tàbí ẹsẹ̀ tí ó rọni ìgbẹ́kẹ̀lé lórí aláìṣòótọ́ ní àsìkò ìdààmú.

    28Bí ìlú tí odi rẹ̀ ti wó lulẹ̀ni ènìyàn tí kò le kó ara rẹ̀ ní ìjánu.

  14. Jeremias 34

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 34
    Mostrando versículos 9–17 de 22

    9Kí oníkálùkù lè jẹ́ kí ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin tí í ṣe Heberu lọ lọ́fẹ̀ẹ́, kí ẹnikẹ́ni kí ó má mú ará Juda arákùnrin rẹ̀ sìn.

    14‘Ní ọdún keje, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín gbọdọ̀ tú àwọn Heberu tí wọ́n ti ta ara wọn fún un yín sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n ti sìn yín fún ọdún mẹ́fà. Ẹ gbọdọ̀ jẹ́ kí wọn kí ó lọ’; ṣùgbọ́n àwọn baba yín kò gbọ́; bẹ́ẹ̀ ni wọn kò fetí sí mi.

    17"Nítorí náà báyìí ni Olúwa wí: Ẹ̀yin kò fetí sí mi nípa ọ̀rọ̀ òmìnira láàrín ẹ̀gbọ́n sí àbúrò, láàrín ẹnìkan sí èkejì rẹ̀. Wò ó, èmi yóò kéde òmìnira fún un yín ni Olúwa wí. Sí idà, sí àjàkálẹ̀-ààrùn, àti sí ìyàn, èmi ó sì fi yín fún ìwọ̀sí ní gbogbo ìjọba ilẹ̀ ayé.

  15. Êxodo 20

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 20
    Mostrando versículos 1–9 de 26

    1Ọlọ́run sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ yìí pé,

    8 20.8: Ek 23.12; 31.12-17; 34.21; 35.2,3; Le 19.3; De 5.12-15. Rántí ọjọ́ ìsinmi láti yà á sí mímọ́.

    9Ọjọ́ mẹ́fà ni ìwọ yóò fi ṣiṣẹ́, kí ìwọ kí ó ṣe gbogbo iṣẹ́ rẹ,

  16. Deuteronômio 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 17–46 de 46

    17Ẹ má sì ṣe ojúsàájú ní ìdájọ́. Ẹ ṣe ìdájọ́ ẹni ńlá àti kékeré bákan náà. Ẹ má ṣe bẹ̀rù ẹnikẹ́ni torí pé ti Ọlọ́run ni ìdájọ́. Ẹjọ́ tí ó bá le jù fún un yín ni kí ẹ mú wá fún mi. Èmi yóò sì gbọ́ ọ.

    30Olúwa Ọlọ́run yín, tí ń ṣáájú yín yóò jà fún un yín; bí ó ti ṣe fún un yín ní Ejibiti lójú ẹ̀yin tìkára yín

    41Nígbà náà ni ẹ sì wí pé, "Àwa ti ṣẹ̀ sí Olúwa. A ó sì gòkè lọ láti jà, gẹ́gẹ́ bí Olúwa Ọlọ́run wa ti pàṣẹ fún wa." Torí náà gbogbo yín ẹ mú ohun ìjà a yín, ẹ rò pé ó rọrùn láti gòkè lọ sí àwọn orílẹ̀-èdè olókè náà.

    46Báyìí ni ẹ sì dúró ní Kadeṣi fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọjọ́ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin ti ṣe.

  17. Salmos 90

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 90
    Mostrando versículos 1–13 de 17

    1Olúwa, ìwọ ti jẹ́ ibùgbé wa ní gbogbo ìran dé ìran.

    7A pa wá run nípa ìbínú rẹnípa ìbínú rẹ ara kò rọ̀ wá.

    13Yípadà, Olúwa! Yóò ti pẹ́ tó?Ṣàánú fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ.

  18. Provérbios 19

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 19
    Mostrando versículos 1–22 de 29

    1Ó sàn kí ènìyàn jẹ́ tálákà tí ìrìn rẹ̀ kò lábùkùju aláìgbọ́n tí ètè rẹ̀ jẹ́ àyídáyidà.

    21Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ète inú ọkàn ènìyàn,ṣùgbọ́n ìfẹ́ Olúwa ní ó máa ń borí.

    22Ohun tí ènìyàn ń fẹ́ ni ìfẹ́ tí kì í yẹ̀;ó sàn láti jẹ́ tálákà ju òpùrọ́ lọ.

  19. Jeremias 10

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 10
    Mostrando versículos 1–17 de 25

    1Gbọ́ ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ fún yín ẹ̀yin ilé Israẹli.

    2Báyìí ni Olúwa wí:"Má ṣe kọ́ ìwà àwọn kèrí,kí àmì ọ̀run kí ó má sì dààmú yín,nítorí pé wọ́n ń dààmú orílẹ̀-èdè.

    12Ọlọ́run dá ayé pẹ̀lú agbára rẹ̀,ó dá àgbáyé pẹ̀lú ọgbọ́n rẹ̀,ó mú kí ọ̀run kí ó fẹ̀ síta nípa òye rẹ̀.

    17Kó ẹrù rẹ kúrò láti fi ilẹ̀ náà sílẹ̀ìwọ tí o ń gbé ní ìlú tí a dó tì.

  20. Êxodo 10

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 10
    Mostrando versículos 11–27 de 29

    11Rárá! Ọkùnrin yín nìkan ni kí ó lọ, láti lọ sin Olúwa, níwọ̀n ìgbà tí ó jẹ́ pé èyí ni ẹ̀yin ń béèrè fún." Wọ́n sì lé Mose àti Aaroni kúrò ní iwájú Farao.

    18Nígbà náà ni Mose kúrò ní iwájú Farao ó sì gbàdúrà sí Olúwa.

    27Ṣùgbọ́n Olúwa sé ọkàn Farao le, kò sì ṣetán láti jẹ́ kí wọn lọ.

Léxico (correspondência exata) Semântico (correspondência relacionada) Versículos omitidos Contexto do capítulo