Pular para o conteúdo
Publicidade

Resultados da busca por "fé"

260 resultados encontrados

  1. Jó 32

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 32
    Mostrando versículos 8–18 de 22

    8Ṣùgbọ́n ẹ̀mí kan ní ó wà nínú ènìyànàti ìmísí Olódùmarè ní ì sì máa fún wọn ní òye.

    13Kí ẹ̀yin kí ó má ṣe wí pé, ‘Àwa wá ọgbọ́n ní àwárí;Ọlọ́run ni ó lè bì í ṣubú kì í ṣe ènìyàn.’

    18Nítorí pé èmi kún fún ọ̀rọ̀ sísọ,ẹ̀mí ń rọ̀ mi ni inú mi.

  2. 1 Coríntios 9

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 9
    Mostrando versículos 3–11 de 27

    3Èyí ni ìdáhùn mi sí àwọn tí ń béèrè ẹ̀tọ́ aposteli mi.

    59.5: 1Kọ 7.7-8; Mt 12.46; 8.14; Jh 1.42.Ṣé àwa kò ní ẹ̀tọ́ láti máa mú ìyàwó tí í ṣe onígbàgbọ́ káàkiri gẹ́gẹ́ bí àwọn aposteli mìíràn? Àti bí arákùnrin Olúwa, àti Kefa.

    119.11: Ro 15.27.Bí àwa ti fún irúgbìn ohun ti ẹ̀mí sínú ọkàn yín, ohun ńlá ha ni bí àwa ó ba ká ohun ti yín tí ṣe ti ara?

  3. Romanos 1

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 1
    Mostrando versículos 2–31 de 32

    2ìyìnrere tí ó ti ṣe ìlérí tẹ́lẹ̀ rí láti ẹnu àwọn wòlíì rẹ̀ nínú Ìwé Mímọ́.

    12èyí nì ni pé, kí a lè jẹ́ ìwúrí fún ara wa nípa ìgbàgbọ́ ẹnìkọ̀ọ̀kan wa.

    31aláìníyè nínú, ọ̀dàlẹ̀, aláìnígbàgbọ́, ọ̀dájú, aláìláàánú.

  4. Cânticos 2

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 2
    Mostrando versículos 1–16 de 17

    1Èmi ni ìtànná Ṣaronibí ìtànná lílì àwọn àfonífojì.Olùfẹ́

    5Fi agbára adùn àkàrà dá mi dúró.Fi èso ápù tù mi láranítorí àìsàn ìfẹ́ ń ṣe mí.

    9Olùfẹ́ mi dàbí abo egbin tàbí ọmọ àgbọ̀nrín.Wò ó! Níbẹ̀ ni ó wà lẹ́yìn ògiri waÓ yọjú ní ojú rèséÓ ń fi ara rẹ̀ hàn lójú rèsé ọlọ́nà.

    16Olùfẹ́ mi ni tèmi èmi sì ni tirẹ̀;Ó ń jẹ láàrín àwọn koríko lílì.

  5. Atos 6

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 6
    Mostrando versículos 3–10 de 15

    3Nítorí náà, ará, ẹ wo ọkùnrin méje nínú yín, olórúkọ rere, tí ó kún fún Ẹ̀mí Mímọ́ àti fún ọgbọ́n, tí àwa lè yàn sí iṣẹ́ yìí.

    6Ẹni tí wọ́n mú dúró níwájú àwọn Aposteli; nígbà tí wọ́n sì gbàdúrà, wọ́n gbé ọwọ́ lé wọn.

    10ṣùgbọ́n wọn kò sí lè ko ọgbọ́n àti Ẹ̀mí tí ó fi ń sọ̀rọ̀ lójú.

  6. Juízes 19

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 19
    Mostrando versículos 3–18 de 30

    3ọkọ rẹ̀ lọ sí ibẹ̀ láti rọ̀ ọ́ pé kí ó padà sí ọ̀dọ̀ òun. Nígbà tí ó ń lọ ó mú ìránṣẹ́ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ méjì lọ́wọ́, obìnrin náà mú un wọ inú ilé baba rẹ̀ lọ, nígbà tí baba obìnrin náà rí i ó fi tayọ̀tayọ̀ gbà á.

    4Àna rẹ̀, baba ọmọbìnrin náà rọ̀ ọ́, ó sì borí rẹ̀ láti dá a dúró fún ìgbà díẹ̀, òun sì dúró fún ọjọ́ mẹ́ta, ó ń jẹ, ó ń mu, ó sì ń sùn níbẹ̀.

    18Ọmọ Lefi náà dá a lóhùn pé, "Bẹtilẹhẹmu ti Juda ni àwa ti ń bọ̀, àwa sì ń lọ sí agbègbè tí ó sá pamọ́ ní àwọn òkè Efraimu níbi ti mo ń gbé. Mo ti lọ sí Bẹtilẹhẹmu ti Juda, èmi sì ń lọ sí ilé Olúwa nísinsin yìí. Kò sí ẹni tí ó gbà mí sí ilé rẹ̀.

  7. 1 Crônicas 8

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 8
    Mostrando versículos 2–25 de 40

    2Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.

    5Gera, Ṣefufani àti Huramu.

    25Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.

  8. Êxodo 18

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 18
    Mostrando versículos 10–24 de 27

    10Jetro sì wí pé, "Ìyìn ni fún Olúwa, ẹni tí ó gba yín là kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Ejibiti àti lọ́wọ́ Farao, ẹni tí ó sì gba àwọn ènìyàn là kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Ejibiti.

    15Mose dá a lóhùn pé, "Nítorí àwọn ènìyàn ń tọ̀ mí wá láti mọ́ ìfẹ́ Ọlọ́run.

    24Mose fetísílẹ̀ sí àna rẹ̀, ó sì ṣe ohun gbogbo tí ó wí fún un.

  9. Ezequiel 16

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 16
    Mostrando versículos 1–35 de 63

    1Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:

    23"Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, ‘Ègbé! Ègbé ni fún ọ. Lẹ́yìn gbogbo ìwà búburú rẹ,

    35" ‘Nítorí náà, ìwọ alágbèrè, gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa!

  10. Provérbios 18

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 18
    Mostrando versículos 2–13 de 24

    2Aláìgbọ́n kò rí inú dídùn sí òyeṣùgbọ́n ó ní inú dídùn sí sísọ èrò tirẹ̀.

    6Ètè aláìgbọ́n dá ìjà sílẹ̀ẹnu rẹ̀ sì ń ṣokùnfà ẹgba.

    7Ẹnu aláìgbọ́n ni ó ba tirẹ̀ jẹ́,ètè rẹ̀ sì jẹ́ ìdẹ̀kùn fún ọkàn rẹ̀.

    13Ẹni tí ó ń sì kí ó tó gbọ́,èyí ni ìwà òmùgọ̀ àti ìtìjú rẹ̀.

  11. Deuteronômio 30

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 30
    Mostrando versículos 14–20 de 20

    1430.14: Ro 10.8.Kì í ṣe bẹ́ẹ̀, ọ̀rọ̀ náà súnmọ́ tòsí rẹ, ó wà ní ẹnu rẹ àti ní ọkàn rẹ kí ìwọ lè máa ṣe é.

    17Ṣùgbọ́n tí ọkàn an yín bá yí padà tí ìwọ kò sì ṣe ìgbọ́ràn, àti bí o bá fà, lọ láti foríbalẹ̀ fún ọlọ́run mìíràn àti sìn wọ́n,

    20kí ìwọ kí ó le máa fẹ́ Olúwa Ọlọ́run rẹ, fetísílẹ̀ sí ohùn un rẹ̀, kí o sì dúró ṣinṣin nínú rẹ̀. Nítorí Olúwa ni ìyè rẹ, yóò sì fún ọ ní ọdún púpọ̀ ní ilẹ̀ tí ó ti búra láti fi fún àwọn baba rẹ Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu.

  12. Gênesis 3

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 3
    Mostrando versículos 5–20 de 24

    5"Nítorí Ọlọ́run mọ̀ wí pé, bí ẹ̀yin bá jẹ nínú rẹ̀, ojú yín yóò là, ẹ̀yin yóò sì dàbí Ọlọ́run, ẹ̀yin yóò sì mọ rere yàtọ̀ sí búburú."

    13 3.13: 2Kọ 11.3; 1Tm 2.14. Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run wí pé, "Èwo ni èyí tí ìwọ ṣe yìí?"Obìnrin náà dáhùn pé, "Ejò ni ó tàn mí jẹ, mo sì jẹ ẹ́."

    20Adamu sì sọ aya rẹ̀ ní Efa nítorí òun ni yóò di ìyá gbogbo alààyè.

  13. Salmos 72

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 72
    Mostrando versículos 15–20 de 20

    15Yóò sì pẹ́ ní ayé!A ó sì fún un ní wúrà Ṣeba.Àwọn ènìyàn yóò sì máa gbàdúrà fún un nígbà gbogbokí a sì bùkún fún un lójoojúmọ́.

    19Olùbùkún ni orúkọ rẹ̀ tí ó lógo títí láé;kí gbogbo ayé kún fún ògo rẹ̀.Àmín àti Àmín.

    20Èyí ni ìparí àdúrà Dafidi ọmọ Jese.

  14. Jeremias 37

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 37
    Mostrando versículos 4–17 de 21

    4Nígbà yìí Jeremiah sì ń wọlé, ó sì ń jáde láàrín àwọn ènìyàn nítorí wọ́n ti fi sínú túbú.

    6Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wòlíì Ọlọ́run wá:

    16Wọ́n fi Jeremiah sínú túbú tí ó ṣókùnkùn biribiri; níbi tí ó wà fún ìgbà pípẹ́.

    17Nígbà náà ni ọba Sedekiah ránṣẹ́ sí i, tí ó sì pàṣẹ pé kí wọ́n mú wá sí ààfin níbi tí ó ti bi í ní ìkọ̀kọ̀ pé, "Ǹjẹ́ ọ̀rọ̀ kan wà láti ọ̀dọ̀ Olúwa?"Jeremiah sì pé, "Bẹ́ẹ̀ ni, wọn ó fi ọ́ lé ọwọ́ ọba Babeli."

  15. Números 28

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 28
    Mostrando versículos 1–30 de 31

    1Olúwa sọ fún Mose pé,

    23Ṣe eléyìí ní àfikún sí ẹbọ sísun àràárọ̀.

    30Ẹ fi òbúkọ kan ṣe ètùtù fún ara yín.

  16. 1 Coríntios 12

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 12
    Mostrando versículos 1–9 de 31

    1Ní ti Ẹ̀mí Mímọ́ ẹ̀yin ará, kò yẹ́ kí ẹ jẹ́ òpè.

    212.2: Ef 2.11-12.Ẹ̀yin kò mọ̀ pé nígbà tí ẹ̀yin jẹ́ kèrí, a fà yín lọ sọ́dọ̀ àwọn odi òrìṣà.

    4Ǹjẹ́ onírúurú ẹ̀bùn ni ó wà, ṣùgbọ́n Ẹ̀mí kan náà ni o ń pín wọn.

    9Ó fi ẹ̀bùn ìgbàgbọ́ fún ẹlòmíràn, ẹlòmíràn ló sì fi agbára ìwòsàn fún nípa Ẹ̀mí Mímọ́ kan náà.

  17. Atos 14

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 14
    Mostrando versículos 7–28 de 28

    7Níbẹ̀ ni wọ́n sì ń wàásù ìyìnrere.

    9Ọkùnrin yìí gbọ́ bí Paulu ti ń sọ̀rọ̀: ẹni, nígbà tí ó tẹjúmọ́ ọn ti ó sì rí i pé, ó ni ìgbàgbọ́ fún ìmúláradá.

    28Níbẹ̀ ni wọ́n ń gbé pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn ni ọjọ́ púpọ̀.

  18. Êxodo 6

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 6
    Mostrando versículos 10–29 de 30

    10Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose.

    28Nígbà tí Olúwa bá Mose sọ̀rọ̀ ni Ejibiti,

    29Olúwa sì sọ fún Mose pé, "Èmi ni Olúwa. Sọ ohun gbogbo ti mo ti sọ fún ọ fún Farao ọba Ejibiti."

  19. Romanos 4

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 4
    Mostrando versículos 3–21 de 25

    34.3: Gẹ 15.6; Ro 4.9,22; Ga 3.6; Jk 2.23.Ìwé Mímọ́ ha ti wí? "Abrahamu gba Ọlọ́run gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un."

    20Kò fi àìgbàgbọ́ ṣiyèméjì nípa ìlérí Ọlọ́run; ṣùgbọ́n ó lágbára sí i nínú ìgbàgbọ́ bí ó ti fi ògo fún Ọlọ́run,

    21pẹ̀lú ìdánilójú kíkún pé, Ọlọ́run lè ṣe ohun tí ó ti ṣe ìlérí rẹ̀.

  20. Jó 40

    ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní
    Capítulo 40
    Mostrando versículos 1–11 de 24

    1Olúwa dá Jobu lóhùn sí pẹ̀lú, ó sì wí pé,

    9Ìwọ ni apá bí Ọlọ́runtàbí ìwọ lè fi ohùn sán àrá bí òun?

    11Mú ìrunú ìbínú rẹ jáde;kíyèsí gbogbo ìwà ìgbéraga rẹ kí o sì rẹ̀ ẹ́ sílẹ̀.

Léxico (correspondência exata) Semântico (correspondência relacionada) Versículos omitidos Contexto do capítulo