Pular para o conteúdo
Publicidade

Neemias 4

Àtakò àtúnkọ́ odi Jerusalẹmu

1 Nígbà Sanballati gbọ́ àwa ń tún odi náà mọ, ó bínú, ó bínú púpọ̀. Ó fi àwọn ará Júù ṣe ẹlẹ́, 2 ó sọ níwájú àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ àti níwájú àwọn ọmọ-ogun Samaria , "ni àwọn aláìlera Júù wọ̀nyí ń ṣe yìí? Ṣé wọn yóò odi wọn padà ni? Ṣé wọn yóò ẹbọ ni? Ṣé wọn yóò parí i rẹ̀ lóòjọ́ ni ? Ṣé wọ́n òkúta a ti sun láti inú òkìtì padà bọ̀ sípò ó jóná wọ́n ṣe ?"

3 Tobiah ará Ammoni, ẹni ó lẹ́gbẹ̀́ rẹ̀, , "Ohun wọ́n ń mọkọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ lásán gùn ún sókè, yóò fọ́ odi òkúta wọn lulẹ̀!"

4 Gbọ́ ti wa, Ọlọ́run wa, nítorí àwa di ẹni ̀gàn. ̀gàn wọn padà sórí ara wọn. o fi wọ́n fún ìkógun ilẹ̀ ìgbèkùn. 5 ṣe bo ̀bi wọn tàbí wẹ àwọn ̀ṣẹ̀ wọn kúrò níwájú rẹ, nítorí wọ́n bínú níwájú àwọn ̀mọ̀.

6 Bẹ́̀ ni àwa mọ odi náà títí gbogbo rẹ̀ fi ìdajì gíga rẹ̀, nítorí àwọn ènìyàn ṣiṣẹ́ pẹ̀gbogbo ọkàn an wọn.

Veja também