Pular para o conteúdo
Publicidade

Oséias 11

Ìfẹ́ Ọlọ́run Israẹli

1 11.1: Mt 2.15. "Nígbà Israẹli ọmọdé mo fẹ́ràn rẹ̀,

mo pe ọmọ mi jáde láti Ejibiti .

2 a ti ń pe wọn,

bẹ́̀ ni wọ́n ṣe ń kúrò lọ́dọ̀ mi,

wọn ẹbọ Baali,

wọn fi tùràrí jóná ère fínfín.

3 Lóòtítọ́ mo kọ́ Efraimu pẹ̀ìrìn

mo di wọ́n apá,

ṣùgbọ́n wọn mọ̀

mo ti wọn láradá.

4 Mo fi okùn ènìyàn wọ́n

àti ìdè ìfẹ́.

Mo àjàgà kúrò ni ọrùn wọn,

Mo fi ara balẹ̀ fún wọn ni oúnjẹ.

5 "Ṣé wọn ò padà Ejibiti .

Ṣé Asiria jẹ ọba wọn lórí

nítorí wọ́n kọ̀ jálẹ̀ láti ronúpìwàdà?

6 Idà yóò kọ mọ̀gbogbo ìlú wọn

yóò si gbogbo irin ẹnu odi ìlú wọn jẹ́

yóò fi òpin gbogbo èrò wọn.

7 Àwọn ènìyàn mi ti pinnu láti pẹ̀yìndà kúrò lọ́dọ̀ mi

wọ́n tilẹ̀ wọ́n sọ́dọ̀ ̀gá-ògo jùlọ,

gbé wọn ga rárá.

8 "Báwo ni èmi ó ṣe fi ́ sílẹ̀, Efraimu?

Báwo ni èmi ó ṣe yọ̀ǹda rẹ̀, Israẹli?

Báwo ni mo ṣe ṣe bi i Adma?

Báwo ni mo ṣe ṣe bi i Seboimu?

Ọkàn mi yípadà nínú mi

àánú mi ru sókè.

9 Èmi ni ìbínú gbígbóná mi ṣẹ,

tàbí èmi sọ Efraimu di ahoro.

Nítorí èmi ni Ọlọ́run, àní, èmi í ṣe ènìyàn.

Ẹni mímọ́ láàrín yín,

Èmi í nínú ìbínú.

10 Wọn yóò máa tẹ̀Olúwa;

òun yóò ramúramù i kìnnìún.

Nígbà ,

àwọn ọmọ rẹ yóò ìwárìrì láti ìwọ̀-oòrùn.

11 Wọn ó pẹ̀̀

i ẹyẹ láti Ejibiti,

i àdàbà láti Asiria,

Èmi ó wọn padà ilé wọn,"

ni Olúwa .

̀ṣẹ̀ Israẹli

12 Efraimu fi irọ́ mi

ilé Israẹli pẹ̀̀tàn.

Ṣùgbọ́n Juda dúró ṣinṣin pẹ̀Ọlọ́run.

Ó ṣe olóòtítọ́ Ẹni mímọ́ Israẹli.

Veja também