Publicidade

Provérbios 1

Èròǹgbà àti kókó-ọ̀rọ̀

1 Àwọn òwe ti Solomoni, ọmọ Dafidi, ọba Israẹli.

2 Láti le ọgbọ́n àti ̀kọ́,

láti òye àwọn ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀.

3 Láti gba ̀kọ́ ọgbọ́n, òdodo,

àti ìdájọ́, àti àìṣègbè;

4 láti fi òye fún onírẹ̀lẹ̀,

ìmọ̀ àti ìṣọ́ra fún àwọn èwe.

5 Jẹ́ ọlọ́gbọ́n tẹ́ó ìmọ̀ kún ìmọ̀,

jẹ́ ẹni òye gba ìtọ́sọ́.

6 Láti mọ ìtumọ̀ òwe àti ìtán-dòwe,

àwọn ̀rọ̀ àti àlọ́ àwọn ọlọ́gbọ́n.

7 Ìbẹ̀Olúwa ni ìbẹ̀rẹ̀ ìmọ̀,

ṣùgbọ́n aláìgbọ́n kẹ́gàn ọgbọ́n àti ̀kọ́.

̀rọ̀ ìyànjú láti ṣàfẹ́ọgbọ́n

8 Tẹ́, ìwọ ọmọ mi ̀kọ́ baba rẹ,

ṣe kọ ̀kọ́ màmá rẹ sílẹ̀.

9 Wọn yóò jẹ́ òdòdó ̀yẹ olóòórùn dídùn lórí rẹ

àti ̀ṣọ́ ó dára ọrùn rẹ .

10 Ọmọ mi, àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ń tàn ́,

ṣe gbà fún wọn.

11 wọn , "pẹ̀wa;

jẹ́ á ba ibùba fún ̀jẹ̀ ẹnìkan,

jẹ́ á lúgọ ìkọ̀kọ̀ de aláìṣẹ̀ àìnídìí;

12 jẹ́ gbé wọn láààyè, ibojì òkú,

àti lódidi, àwọn ń sọ̀kalẹ̀ lọ sínú kòtò;

13 a ó ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan níye lórí

a ó fi ìkógun kún inú ilé wa,

14 da ìpín rẹ pọ̀ mọ́ àárín wa,

a ó jọ pawó sínú àpò kan náà,"

15 ọmọ mi, ṣe wọn lọ,

ṣe rìn ojú ̀wọn.

16 Nítorí ẹsẹ̀ wọn ń sáré ̀ṣẹ̀,

wọ́n yára láti ta ̀jẹ̀ sílẹ̀.

17 Wàhálà asán ni ènìyàn máa dẹ àwọ̀n sílẹ̀,

ojú ẹyẹ!

18 Àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ń lúgọ fún ̀jẹ̀ ara wọn.

Ara wọn ni wọ́n ń lọ́.

19 Báyìí ni ìgbẹ̀yìn gbogbo àwọn ń èrè àìtọ́;

yóò ̀gbogbo ẹni ó i lọ.

Ìkìlọ̀ láti ṣe kọ ọgbọ́n sílẹ̀

20 Ọgbọ́n kígbe sókè pópó

ó gbé ohùn rẹ̀ sókè láàrín ọjà;

21 láàrín ọjà ni ó ti kígbe jáde

ibodè ìlú ni ó ti sọ̀rọ̀ rẹ̀:

22 "Yóò ha ti pẹ́ ̀yin aláìmọ̀kan yóò fi fẹ́ àìmọ̀kan yín ?

Yóò ha ti pẹ́ àwọn ẹlẹ́gàn yóò ṣe inú dídùn ìpẹ̀gàn ?

Àwọn aláìgbọ́n kórìíra ìmọ̀?

23 ti gbọ́ ìbáwí ì mi ni,

ǹ ti ohun ó nínú ọkàn mi jáde fún yín

n fi inú mi hàn i yín.

24 Ṣùgbọ́n níwọ̀n ti kọ ìpè ìgbà mo

ẹni ó kọ ibi ara mi gbà mo na ọwọ́ wọn,

25 níwọ́n ti kọ gbogbo ìmọ̀ràn mi,

̀yin gba ìbáwí mi,

26 Èmi pẹ̀yóò fi ìdààmú yín rẹ́rìn-ín;

èmi yóò ṣẹ̀fẹ̀ nígbà ìyọnu a yín.

27 Nígbà ìyọnu a yín ìjì líle,

nígbà ìdààmú ààjà,

nígbà wàhálà àti ìbànújẹ́ ọkàn ́ mọ́lẹ̀.

28 "Nígbà náà ni wọn yóò ṣùgbọ́n, èmi dáhùn;

wọn yóò fi ara balẹ̀ mi ṣùgbọ́n wọn yóò mi.

29 Níwọ́n wọ́n ti kórìíra ìmọ̀

wọ́n kọ̀ láti bẹ̀Olúwa.

30 Níwọ́n wọn ti gbà ìmọ̀ràn mi

wọ́n kẹ́gàn ìmọ̀ràn mi,

31 wọn yóò jẹ èrè iṣẹ́ ọwọ́ wọn

wọn yóò jèrè èso ètè wọn kíkún.

32 Nítorí ìrìnkurìn àwọn aláìmọ̀kan ni yóò pa wọ́n

ìkáwọ́gbera aláìgbọ́n ni yóò pa á run;

33 ṣùgbọ́n ẹnìkan ó fetí mi, yóò gbé láìléwu

yóò nínú ìdẹ̀ra, láìsí ìbẹ̀ìpalára."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-