Publicidade

Provérbios 10

1 Àwọn òwe Solomoni.

Ọlọ́gbọ́n ọmọ ń inú baba rẹ̀ dùn,

ṣùgbọ́n aṣiwèrè ọmọ ń ba inú ìyá rẹ̀ jẹ́.

2 Ìṣúra a kójọ nípa ìwà búburú èrè,

ṣùgbọ́n òdodo a máa gbani lọ́wọ́ ikú.

3 Olúwa í jẹ́ ebi máa pa olódodo,

ṣùgbọ́n ó ba ète àwọn ènìyàn búburú jẹ́.

4 Ọwọ́ ó lẹ máa ń sọ ènìyàn di tálákà,

ṣùgbọ́n ọwọ́ ó múra ṣíṣẹ́ a máa sọ ni di ọlọ́rọ̀.

5 Ẹni ó irúgbìn jọ àsìkò òjò jẹ́ ọlọ́gbọ́n ọmọ,

ṣùgbọ́n ẹni ó sùn àsìkò ìkórè jẹ́ adójútini ọmọ.

6 Ìbùkún ó máa ń kún orí olódodo,

ṣùgbọ́n ìwà ipá máa ń kún ẹnu ènìyàn búburú.

7 Ìrántí olódodo yóò jẹ́ ìbùkún,

ṣùgbọ́n orúkọ ènìyàn búburú yóò jẹrà.

8 Ẹni ó gbọ́n nínú ọkàn rẹ̀ máa ń gba àṣẹ,

ṣùgbọ́n ètè wérewère yóò parun.

9 Ẹni ó ń rìn déédé, ń rìn láìléwu,

ṣùgbọ́n àṣírí ẹni ń rin ̀pálapàla yóò .

10 Ẹni ń ṣẹ́pàkòpàkò fún ibi ń fa àìbalẹ̀ ọkàn,

aláìgbọ́n ń ṣàròyé kiri yóò parun.

11 Ẹnu olódodo jẹ́ orísun ìyè,

ṣùgbọ́n ìwà ipá ni ó gba gbogbo ẹnu ènìyàn búburú.

12 Ìríra a máa ìjà sílẹ̀,

ṣùgbọ́n ìfẹ́ a máa bo gbogbo àṣìṣe mọ́lẹ̀.

13 Ọgbọ́n ni a ń lẹ́nu àwọn olóye,

ṣùgbọ́n kùmọ̀ fún ̀yìn àwọn aláìlóye.

14 Ọlọ́gbọ́n ènìyàn ìmọ̀ jọ,

ṣùgbọ́n ẹnu aláìgbọ́n a máa ṣokùnfà ìparun.

15 Ọrọ̀ àwọn olódodo ni ìlú olódi wọn,

ṣùgbọ́n òsì ni ìparun aláìní.

16 Èrè olódodo ń ìyè fún wọn,

ṣùgbọ́n èrè ènìyàn búburú ń ìjìyà fún wọn.

17 Ẹni ó gbọ́ ìbáwí fi ̀ìyè hàn,

ṣùgbọ́n ẹni ó kọ ìbáwí àwọn mìíràn ṣìnà.

18 Ẹni ó pa ìkórìíra rẹ̀ mọ́ jẹ́ òpùrọ́

ẹni ó ń ba ni jẹ́ jẹ́ aláìgbọ́n.

19 Nínú ̀rọ̀ púpọ̀ a le fẹ́ ̀ṣẹ̀

ṣùgbọ́n ẹni ó pa ẹnu rẹ̀ mọ́ jẹ́ ọlọ́gbọ́n.

20 Ètè olódodo jẹ́ ààyò fàdákà,

ṣùgbọ́n ọkàn ènìyàn búburú níye lórí.

21 Ètè olódodo ń bọ́ ̀pọ̀lọpọ̀,

ṣùgbọ́n aláìgbọ́n ń nítorí àìlóye.

22 Ìbùkún Olúwa ń ọrọ̀ ,

í í fi ìdààmú i.

23 Aláìgbọ́n a máa inú dídùn ìwà búburú,

ṣùgbọ́n olóye ènìyàn a máa inú dídùn ọgbọ́n.

24 Ohun ènìyàn búburú bẹ̀yóò a;

olódodo yóò ohun ó fẹ́ gbà.

25 Nígbà ìjì ti kọjá, ènìyàn búburú a kọjá lọ,

ṣùgbọ́n olódodo yóò dúró ṣinṣin láéláé.

26 ọtí kíkan eyín, àti èéfín ojú,

bẹ́̀ ni ̀lẹ ẹni ó rán an níṣẹ́.

27 Ìbẹ̀Olúwa ń ọjọ́ ayé gígùn ,

ṣùgbọ́n a ọjọ́ ayé ènìyàn búburú kúrú.

28 Ìrètí olódodo ni ayọ̀,

ṣùgbọ́n ìrètí ènìyàn búburú jásí òfo.

29 ̀Olúwa jẹ́ ààbò fún olódodo,

ṣùgbọ́n ìparun ni ó jẹ́ fún àwọn ń ṣe ibi.

30 A yóò fa olódodo tu láéláé,

ṣùgbọ́n ènìyàn búburú yóò dúró pẹ́ lórí ilẹ̀.

31 Ẹnu olódodo ń ọgbọ́n jáde ,

ṣùgbọ́n ètè àyípadà ni a ó kúrò.

32 Ètè olódodo mọ ohun ìtẹ́wọ́gbà,

ṣùgbọ́n ètè ènìyàn búburú mọ̀ ju èké lọ.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-