Publicidade

Provérbios 16

1 Ti ènìyàn ni ìgbèrò inú ọkàn

ṣùgbọ́n láti ̀dọ̀ Olúwa ni ìdáhùn ahọ́n ti ń .

2 Gbogbo ̀ènìyàn ni ó dàbí i ó dára lójú ara rẹ̀

ṣùgbọ́n Olúwa ń díwọ̀n èrò inú ọkàn.

3 Fi ohun gbogbo o ṣe Olúwa lọ́wọ́,

èrò rẹ yóò ṣe é ṣe.

4 Olúwa ti ṣe ohun gbogbo láti ó ó ṣe fẹ́

kódà ènìyàn búburú fún ọjọ́ ìpọ́njú.

5 Olúwa kórìíra gbogbo ẹni ń gbéraga lọ́kàn rẹ̀

mọ èyí dájú wọn lọ láìjìyà.

6 Nípasẹ̀ ìfẹ́ àti òtítọ́ a ṣe ètùtù ̀ṣẹ̀

nípasẹ̀ ìbẹ̀Olúwa ènìyàn fún ibi.

7 Nígbà ̀ènìyàn tẹ́ Olúwa lọ́rùn,

yóò àwọn ̀rẹ̀ gàn án a gbé àlàáfíà.

8 Ó sàn ó kéré pẹ̀òdodo

ju èrè púpọ̀ pẹ̀èrú lọ.

9 Ènìyàn a máa pète ̀ara rẹ̀ lọ́kàn an rẹ̀

ṣùgbọ́n Olúwa í pinnu ìgbésẹ̀ rẹ̀.

10 Ètè ọba a máa sọ̀rọ̀ nípa àṣẹ i

ẹnu rẹ̀ gbọdọ̀ ṣèké.

11 Òdínwọ̀n àti òsùwọ̀n òtítọ́ láti ̀dọ̀ Olúwa;

gbogbo wíwúwo àpò jẹ́ láti ọwọ́ rẹ̀.

12 Àwọn ọba kórìíra ìwà àìtọ́

nítorí òdodo í fi ìdí ìtẹ́ múlẹ̀.

13 Àwọn ọba inú dídùn ètè ń ṣọ òtítọ́,

wọ́n fẹ́ ẹni ń sọ̀rọ̀ òtítọ́.

14 Ìránṣẹ́ ikú ni ìbínú ọba jẹ́

ṣùgbọ́n ọlọ́gbọ́n ènìyàn yóò ú nínú.

15 Nígbà ojú ọba túká, ó túmọ̀ ìyè;

ojúrere rẹ̀ dàbí i ṣíṣú òjò ìgbà òjò.

16 Ó ti dára láti ọgbọ́n ju wúrà lọ

àti láti yan òye dípò o fàdákà!

17 Òpópó ̀àwọn ẹni dídúró ṣinṣin yàgò fún ibi,

ẹni ó ṣọ́ ̀rẹ̀, ṣọ́ ẹnu ara rẹ̀.

18 Ìgbéraga í ṣáájú ìparun,

agídí ọkàn í ṣáájú ìṣubú.

19 Ó sàn láti jẹ́ onírẹ̀lẹ̀ ọkàn láàrín àwọn olùpọ́njú

láti máa pín ìpín pẹ̀àwọn agbéraga.

20 Ẹnikẹ́ni ó tẹ̀̀kọ́ yóò ìre,

ìbùkún ni fún ẹni ó gbẹ́kẹ̀Olúwa.

21 Àwọn ó gbọ́n nínú ọkàn ń olóye

̀rọ̀ ìtura ń ̀kọ́ gbèrú.

22 Òye jẹ́ orísun ìyè fún àwọn ó i,

ṣùgbọ́n ìwà òmùgọ̀ ń ìyà jẹ aláìgbọ́n.

23 Ọkàn ọlọ́gbọ́n ènìyàn a máa ṣọ́ ẹnu rẹ̀

ètè rẹ̀ ń ̀kọ́ dàgbà.

24 ̀rọ̀ ìtura dàbí afárá oyin

ó dùn fún ọkàn, ó fi ìlera fún egungun.

25 ̀kan ó dàbí i ó dára lójú ènìyàn

ṣùgbọ́n ìgbẹ̀yìn a ṣokùnfà ikú.

26 Ọkàn alágbàṣe ń ṣiṣẹ́ fún ara rẹ̀;

nítorí ebi rẹ̀ ó máa ṣiṣẹ́ lọ.

27 Ènìyàn búburú ń pète

̀rọ̀ rẹ̀ dàbí i iná ń jóni.

28 Aláyídáyidà ènìyàn ìjà sílẹ̀

olófòófó a máa pín ̀rẹ́ kòríkòsùn .

29 Oníjàgídíjàgan ènìyàn tan aládùúgbò rẹ̀

ó un sọ̀kalẹ̀ lọ ̀dára.

30 Ẹni ń ṣẹ́ń pètekéte;

ẹni ó ṣu ẹnu jọ ń pète aburú.

31 Adé ògo ni ewú orí jẹ́,

ìgbé ayé òdodo í ni bẹ̀.

32 Ó sàn láti jẹ́ onísùúrù ju ajagun ènìyàn lọ,

ẹni ó pa ìbínú mọ́ra ju ajagun ṣẹ́gun ìlú lọ.

33 A ṣẹ́ kèké si ìṣẹ́po aṣọ,

ṣùgbọ́n gbogbo ìdájọ́ rẹ̀ láti ̀dọ̀ Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-