Publicidade

Provérbios 2

Èrè ìwà rere ọgbọ́n ń

1 Ọmọ mi, ìwọ gba ̀rọ̀ mi,

ìwọ pa òfin mi mọ́ inú rẹ,

2 ìwọ dẹtí rẹ sílẹ̀ ọgbọ́n

ìwọ fi ọkàn rẹ òye,

3 àní, ìwọ tọ ìmọ̀ lẹ́yìn,

ìwọ gbé ohùn rẹ sókè fún òye

4 ìwọ ṣàfẹ́rẹ̀ i fàdákà

ìwọ wa kiri ìṣúra a fi pamọ́.

5 Nígbà náà ni ìwọ yóò bẹ̀Olúwa,

ìwọ yóò ìmọ̀ Ọlọ́run.

6 Nítorí Olúwa ni ó ń fún ni ọgbọ́n,

láti ẹnu rẹ̀ ni ìmọ̀ àti òye ti ń .

7 Ó to ìgbàlà fún àwọn olódodo,

Òun ni asà fún àwọn ń rìn déédé,

8 Ó pa ipa ̀ìdájọ́ mọ́

Ó ń pa ̀àwọn àyànfẹ́ rẹ̀ mọ́.

9 Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ òdodo àti ìdájọ́,

àti àìṣègbègbogbo ipa ̀rere.

10 Nítorí ọgbọ́n yóò wọ inú ọkàn rẹ

ìmọ̀ yóò jẹ́ ìtura fún ọkàn rẹ.

11 Ìmòye yóò pa mọ́

òye yóò máa ṣọ́ .

12 Ọgbọ́n yóò gbà ́ kúrò ̀àwọn ènìyàn búburú,

lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn ọrọ̀ wọn jẹ́ àyídáyidà,

13 ẹni ó kúrò ̀ìdúró ṣinṣin

láti rìn ̀ó ṣókùnkùn,

14 ẹni ó yọ̀ nínú ṣíṣe búburú,

ó ṣe inú dídùn àyídáyidà àwọn ènìyàn ibi,

15 ̀ẹni ó wọ́

wọ́n jẹ́ alárékérekè ̀wọn.

16 Yóò gba ìwọ pẹ̀kúrò lọ́wọ́ àwọn àjèjì obìnrin,

àní, lọ́wọ́ obìnrin àjèjì ń fi ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ tannijẹ,

17 ẹni ó ti kọ ọkọ àkọ́fẹ́ ìgbà èwe rẹ̀ sílẹ̀

ó gbàgbé májẹ̀ó ti níwájú Ọlọ́run rẹ̀.

18 Nítorí ilé rẹ̀ jẹ́ ̀ikú

ipa ̀rẹ̀ sọ́dọ̀ àwọn òkú.

19 sẹ́ni lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ ó padà

bẹ́̀ ni wọn í ̀ìyè.

20 Bẹ́̀ ni ìwọ yóò rìn ̀àwọn ènìyàn rere

ìwọ ó pa ̀àwọn olódodo mọ́.

21 Nítorí ẹni dídúró ṣinṣin yóò gbé ilé náà

àwọn aláìlẹ́gàn ni yóò máa nínú rẹ̀.

22 Ṣùgbọ́n a ó ènìyàn búburú kúrò lórí ilẹ̀ náà

a ó fa àwọn aláìṣòótọ́ tu kúrò lórí rẹ̀.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-