Publicidade

Provérbios 20

1 Ẹlẹ́ni ọtí wáìnì, aláriwo ọtí líle;

ẹnikẹ́ni ó fi tànjẹ gbọ́n.

2 Ìbẹ̀ọba dàbí kíké e kìnnìún;

ẹnikẹ́ni ó un bínú ba ayé ara rẹ̀ jẹ́.

3 Iyì ni ó jẹ́ fún ènìyàn láti fún ìjà,

ṣùgbọ́n gbogbo aláìgbọ́n a máa tètè ìjà.

4 ̀lẹ í ṣiṣẹ́ oko nígbà ó yẹ,

nítorí náà àsìkò ìkórè, yóò nǹkan.

5 Ète ọkàn ènìyàn dàbí omi jíjìn;

ṣùgbọ́n ènìyàn olóye á wọn jáde.

6 ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni wọ́n máa ń sọ pe àwọn ìfẹ́ àìṣẹ̀tàn,

ṣùgbọ́n rọrùn láti ènìyàn olóòtítọ́.

7 Olódodo ènìyàn a máa gbé ìgbé ayé àìlábùkù

ìbùkún ni fún àwọn ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀.

8 Nígbà ọba jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀ láti ṣe ìdájọ́

yóò fẹ́ gbogbo ibi dànù pẹ̀ojú rẹ̀.

9 Ta ni ó le è , "Mo ti ṣe ọkàn mi mímọ́,

mo mọ́, n lẹ́ṣẹ̀"?

10 Ìwọ̀n èké àti òsùwọ̀n ìrẹ́jẹ

Olúwa kórìíra méjèèjì.

11 Kódà a mọ ọmọdé nípa iṣẹ́ rẹ̀

nípa pe bóyá iṣẹ́ rẹ mọ́ tàbí ó tọ̀.

12 Etí ó ń gbọ́ àti ojú ó ń ríran

Olúwa ni ó méjèèjì.

13 ṣe fẹ́ràn oorun, àìṣe bẹ́̀ ìwọ yóò di tálákà.

Ma ṣe sùn ìwọ yóò oúnjẹ láti tún fi tọrọ.

14 "dára, dára!" ẹni ra ọjà máa ń ;

nígbà ó kúrò níbẹ̀ tán,

yóò máa yangàn òun ṣe .

15 Wúrà , iyùn rẹpẹtẹ,

ṣùgbọ́n, ahọ́n ń sọ ìmọ̀ gan an ni ̀ṣọ́ iyebíye.

16 Gba abọ́ ẹni ó ṣe onídùúró fún àlejò;

un lọ́wọ́ ìbúra ó ṣe é fún obìnrin onírìnkurìn.

17 Oúnjẹ a fi ̀èrú máa ń dùn lẹ́nu ènìyàn,

ṣùgbọ́n, a yọrí ibi ẹnu ó kún fún erùpẹ̀.

18 Pa ètè rẹ mọ́ nípa wíwá ìmọ̀ràn

o ń jagun, gba ìtọ́sọ́.

19 Olófòófó a máa àṣírí

nítorí náà yẹra fún ènìyàn ń rojọ́ púpọ̀.

20 ènìyàn kan ṣépè fún baba tàbí ìyá rẹ̀,

ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ ni a ó pa nínú òkùnkùn biribiri.

21 Ogún a kójọ kíákíá ìbẹ̀rẹ̀

yóò ìbùkún ìgbẹ̀yìn gbẹ́yín.

22 ṣe , "N ó sẹ̀san àṣìṣe rẹ yìí fún ."

Dúró de Olúwa yóò gbà ́ .

23 Olúwa kórìíra òdínwọ̀n èké.

Òsùwọ̀n ìrẹ́jẹ tẹ́ lọ́rùn.

24 Olúwa ni ó ń ṣe olùdarí ìgbésẹ̀ ènìyàn.

Báwo ni òye gbogbo ̀ènìyàn ṣe le ni?

25 Ìdẹ̀kùn ni fún ènìyàn láti ṣe ìlérí kíákíá

nígbà ó ó máa ro ̀jẹ̀ rẹ̀ .

26 Ọlọ́gbọ́n ọba ènìyàn búburú ;

Ó fi òòlọ ìpakà lọ̀ wọ́n.

27 Àtùpà Olúwa ń ṣe àwárí ̀ènìyàn

a máa ṣàwárí ibi ìkọ̀kọ̀ inú.

28 Ìfẹ́ àti òdodo pa ọba mọ́,

nípa ìfẹ́, ìtẹ́ rẹ̀ láìléwu.

29 Ògo àwọn ̀dọ́mọkùnrin ni agbára wọn,

ewú orí ni iyì arúgbó.

30 Ìgbájú ìgbámú àti ìfarapa máa ń ibi lọ,

pàṣán máa ń ṣe àfọ̀mọ́ ibi ìkọ̀kọ̀ inú.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-