Publicidade

Provérbios 24

1 ṣe ṣe ìlara àwọn ènìyàn búburú

ṣe jẹ́ àwùjọ wọn ́;

2 nítorí ọkàn wọn ń gbèrò ohun búburú,

ètè wọn ń sọ̀rọ̀ nípa dídá rúgúdù sílẹ̀.

3 Nípa ọgbọ́n ni ilé di kíkọ́

nípa òye ni ó ti fìdímúlẹ̀;

4 nípa ìmọ̀ ni àwọn yàrá rẹ̀ kún

pẹ̀àwọn ohun ̀ṣọ́ ó lẹ́ó ṣọ̀wọ́n.

5 Ọlọ́gbọ́n ènìyàn agbára púpọ̀,

ènìyàn ó ìmọ̀ ń agbára i.

6 Láti jagun, ó nílò ìtọ́sọ́:

nínú ìṣẹ́gun ni ̀pọ̀ onígbìmọ̀.

7 Ọgbọ́n ga ju fún aṣiwèrè

àti gbọ̀ngàn ìlú níbi ibodè ohun yóò .

8 Ẹni ń pète ibi

ni a ó mọ̀ ènìyàn ibi.

9 Ète òmùgọ̀ ènìyàn jẹ́ ̀ṣẹ̀,

àwọn ènìyàn kórìíra ẹlẹ́gàn.

10 ìwọ dákú lásìkò ìdààmú

báwo ni agbára rẹ ha ti kéré !

11 Gba àwọn a ń wọ́ lọ ibi ikú ;

fa àwọn ń ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n lọ ibi ìparun padà.

12 ìwọ , "Ṣùgbọ́n a mọ nǹkan kan nípa èyí,"

ǹjẹ́ ẹni ń díwọ̀n ọkàn kíyèsi i? Ǹjẹ́ ẹni ń ṣọ́ ̀rẹ mọ̀ ́n?

Ǹjẹ́ san án fún ẹnìkọ̀̀kan gẹ́gẹ́ ohun ó ti ṣe?

13 Jẹ oyin, ìwọ ọmọ mi, nítorí ó dára,

oyin láti inú afárá oyin dùn lẹ́nu.

14 Mọ̀ pẹ̀ọgbọ́n pẹ̀dùn fún ọkàn rẹ

ìwọ i ìrètí ọjọ́ iwájú fún

ìrètí rẹ yóò ṣófo.

15 ṣe ba ibùba ènìyàn búburú

láti gba ibùjókòó olódodo,

ṣe fi ibi ìsinmi rẹ̀ ṣe ìjẹ;

16 nítorí olódodo ènìyàn tilẹ̀ ṣubú ìgbà méje, yóò tún padà dìde á ni,

ṣùgbọ́n ìdààmú yóò fa ènìyàn búburú lulẹ̀.

17 ṣe yọ̀ nígbà ̀rẹ ṣubú;

nígbà ó kọsẹ̀, ṣe jẹ́ ọkàn rẹ ó yọ̀.

18 Àìṣe bẹ́̀ Olúwa yóò i yóò bínú

yóò ìbínú rẹ̀ padà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀.

19 ṣe fòyà nítorí àwọn ènìyàn ibi

tàbí jowú àwọn ènìyàn búburú,

20 nítorí ẹni ibi ìrètí ọjọ́ iwájú

a ó pa fìtílà àwọn ènìyàn búburú .

21 Bẹ̀Olúwa àti ọba, ọmọ mi,

ṣe darapọ̀ pẹ̀àwọn olórí kunkun.

22 Nítorí àwọn méjèèjì yóò rán ìparun òjijì sórí wọn,

ta ni ó mọ irú ìyọnu wọ́n ?

23 Àwọn wọ̀nyí pẹ̀tún jẹ́ ̀rọ̀ ọlọ́gbọ́n:

láti ṣe ojúsàájú níbi ìdájọ́ dára rárá.

24 Ẹnikẹ́ni ó fún ẹlẹ́bi , "Ìwọ lo jàre,"

àwọn ènìyàn yóò ṣẹ́ èpè fún un àwọn orílẹ̀-èdè yóò kọ̀ ́.

25 Ṣùgbọ́n yóò dára fún àwọn ń ẹlẹ́bi lẹ́bi,

̀pọ̀ ìbùkún yóò sórí wọn.

26 Ìdáhùn òtítọ́

dàbí ìfẹnukoni ẹnu.

27 Parí gbogbo iṣẹ́ ajé rẹ

i oko rẹ ti ṣe dáradára;

lẹ́yìn náà kọ́ ilé rẹ.

28 ṣe rojọ́ èké mọ́ aládùúgbò rẹ láìnídìí,

tàbí o fi ètè rẹ tannijẹ.

29 ṣe , "Èmi yóò ṣe é fún un gẹ́gẹ́ ó ti ṣe fún mi;

Èmi yóò san ohun ó ṣe fún mi padà fún un."

30 Mo kọjá níbi oko ̀lẹ,

mo kọjá níbi ọgbà àjàrà aláìgbọ́n ènìyàn;

31 ̀gún ti ibi gbogbo,

koríko ti gba gbogbo oko náà.

32 Mo fi ọkàn mi nǹkan mo kíyèsi

mo kẹ́kọ̀́ lára ohun mo ;

33 oorun díẹ̀, òògbé díẹ̀,

ìkáwọ́gbera díẹ̀ láti sinmi,

34 òsì yóò adigunjalè

àti àìní olè.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-