Publicidade

Provérbios 4

Ọgbọ́n ni o ga jùlọ

1 Tẹ́, ̀yin ọmọ mi, ̀kọ́ baba; fetísílẹ̀ o òye i.

2 Mo fún ̀kọ́ ó kooro,

nítorí náà, ṣe kọ ̀kọ́ mi sílẹ̀.

3 Nígbà mo jẹ́ ̀dọ́mọkùnrin ilé baba à ,

mo jẹ́ èwe, mo jẹ́ ̀kan ṣoṣo lọ́wọ́ ìyá mi.

4 Ó kọ́ mi ó ,

"Jẹ́ àyà rẹ ó gba ̀rọ̀ mi dúró,

pa òfin mi mọ́, ìwọ ó .

5 Gba ọgbọ́n, gba òye,

ṣe gbàgbé ̀rọ̀ mi tàbí o yẹsẹ̀ kúrò nínú rẹ̀.

6 ṣe kọ ọgbọ́n sílẹ̀, yóò dáàbò ́,

fẹ́ràn rẹ̀, yóò bojútó .

7 Ọgbọ́n ni ó ga ; nítorí náà gba ọgbọ́n.

ó tilẹ̀ gbogbo ohun o , gba òye.

8 Gbé e ga, yóò gbé ga

dìrọ̀ mọ́ ọn, yóò bu iyì fún .

9 Yóò fi òdòdó ̀ṣọ́ ẹwà orí rẹ

yóò fi adé ẹlẹ́fún ."

10 Tẹ́, ọmọ mi, gba ohun mo sọ,

ọjọ́ ayé è rẹ yóò gùn.

11 Mo tọ́ ṣọ́̀ti ọgbọ́n

mo lọ ̀ti tààrà.

12 Nígbà o rìn, ìgbésẹ̀ rẹ ìdíwọ́

nígbà o sáré, ìwọ yóò kọsẹ̀.

13 Di ̀kọ́ , ṣe jẹ́ ó lọ;

tọ́u rẹ̀ dáradára nítorí òun ni ìyè rẹ.

14 ṣe gbé ẹsẹ̀ rẹ ojú ọnà àwọn ènìyàn búburú

tàbí o rìn ̀àwọn ẹni ibi.

15 Yẹra fún un, ṣe rìn níbẹ̀;

yàgò fún un o ̀tìrẹ lọ.

16 Nítorí wọn le sùn àyàfi wọ́n ṣe ibi,

wọn tòògbé àyàfi wọ́n gbé ẹlòmíràn ṣubú.

17 Wọ́n ń jẹ oúnjẹ ìwà búburú

wọ́n ń mu wáìnì ìwà ìkà.

18 Ipa ̀olódodo dàbí àṣẹ̀ṣẹ̀yọ oòrùn

ń tànmọ́lẹ̀ i títí ọjọ́ fi kanrí

19 ṣùgbọ́n ̀ènìyàn búburú dàbí òkùnkùn biribiri;

wọn mọ ohun ó ń wọn kọsẹ̀.

20 Ọmọ mi, tẹ́ohun mo sọ;

fetísílẹ̀ dáradára ̀rọ̀ mi.

21 ṣe jẹ́ wọ́n mọ́ lójú

pa wọ́n mọ́ sínú ọkàn rẹ,

22 nítorí ìyè ni wọ́n jẹ́ fún gbogbo ẹni ó wọn

àti ìlera fún gbogbo ara ènìyàn.

23 Ju gbogbo nǹkan tókù lọ, pa ọkàn rẹ mọ́,

nítorí òun ni orísun ìyè.

24 àrékérekè kúrò ẹnu rẹ;

jẹ́ ̀rọ̀ ìsọkúsọ jìnnà réré ẹnu rẹ.

25 Jẹ́ ojú rẹ máa wo iwájú,

jẹ́ ìwo ojú rẹ máa wo ̀kánkán iwájú rẹ á.

26 Kíyèsi ìrìn ẹsẹ̀ rẹ

rìn àwọn ̀ó dára nìkan.

27 ṣe sọ́tùn ún tàbí sósì;

pa ẹsẹ̀ rẹ mọ́ kúrò nínú ibi.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-