Publicidade

Ensinar

Por Bíblia Online

Ensinar é mandamento e dom. A Bíblia exorta pais, líderes e mestres a transmitir a verdade divina com fidelidade, paciência e sabedoria para as próximas gerações.

Ensinar a Palavra

Toda Escritura é útil para ensinar. Quem ouve as palavras de Jesus e as pratica é como o homem sábio que construiu sobre a rocha.

Gbogbo ìwé mímọ́ ni ó ìmísí Ọlọ́run ó èrè fún ̀kọ́, fún ìbániwí, fún ìtọ́ni, fún ìkọ́ni ó nínú òdodo. ènìyàn Ọlọ́run , a ti múra sílẹ̀ pátápátá fun iṣẹ́ rere gbogbo.

Ọlọ́gbọ́n àti òmùgọ̀ ̀mọ̀

"Nítorí ẹnikẹ́ni ó gbọ́ ̀rọ̀ tèmi wọ̀nyí, ó ṣe wọn, èmi ó fiwé ọlọ́gbọ́n ènìyàn kan, ti ó kọ́ ilé rẹ̀ orí àpáta.

jẹ́ ̀rọ̀ Kristi máa gbé inú yín ̀pọ̀lọpọ̀ nínú ọgbọ́n gbogbo; máa kọ́ , máa gba ara yín níyànjú nínú Saamu, àti orin ìyìn, àti orin ̀, máa kọrin Ọlọ́run ọkàn ọpẹ́.

Nítorí ohun gbogbo a kọ tẹ́lẹ̀, ni a kọ láti fi kọ́ wa , nípa sùúrù àti ìtùnú ìwé mímọ́, àwa ìrètí.

Èròǹgbà àti kókó-ọ̀rọ̀

Àwọn òwe ti Solomoni, ọmọ Dafidi, ọba Israẹli.

Láti le ọgbọ́n àti ̀kọ́,

láti òye àwọn ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀.

Láti gba ̀kọ́ ọgbọ́n, òdodo,

àti ìdájọ́, àti àìṣègbè;

láti fi òye fún onírẹ̀lẹ̀,

ìmọ̀ àti ìṣọ́ra fún àwọn èwe.

Jẹ́ ọlọ́gbọ́n tẹ́ó ìmọ̀ kún ìmọ̀,

jẹ́ ẹni òye gba ìtọ́sọ́.

Láti mọ ìtumọ̀ òwe àti ìtán-dòwe,

àwọn ̀rọ̀ àti àlọ́ àwọn ọlọ́gbọ́n.

Ìbẹ̀Olúwa ni ìbẹ̀rẹ̀ ìmọ̀,

ṣùgbọ́n aláìgbọ́n kẹ́gàn ọgbọ́n àti ̀kọ́.

Instruir as gerações

Ensina a criança nos caminhos de Deus. A geração que não conhece o Senhor perde a herança espiritual da fé.

Fẹ́ràn Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀gbogbo àyà rẹ àti gbogbo ọkàn rẹ, àti gbogbo agbára rẹ. Àwọn àṣẹ mo fún un yín lónìí gbọdọ̀ máa lóókan àyà yín. fi kọ́ àwọn ọmọ yín gidigidi. jókòó nínú ilé, jíròrò nípa wọn, àti nígbà ń rìn ojú ̀, dùbúlẹ̀ àti nígbà dìde.

̀rọ̀ ìyànjú láti ṣàfẹ́ọgbọ́n

Tẹ́, ìwọ ọmọ mi ̀kọ́ baba rẹ,

ṣe kọ ̀kọ́ màmá rẹ sílẹ̀.

Wọn yóò jẹ́ òdòdó ̀yẹ olóòórùn dídùn lórí rẹ

àti ̀ṣọ́ ó dára ọrùn rẹ .

Ìkìlọ̀ nítorí àgbèrè

Ọmọ mi, pa àṣẹ baba rẹ mọ́

ṣe kọ ̀kọ́ ìyá rẹ sílẹ̀.

Jẹ́ wọn nínú ọkàn rẹ láéláé

so wọ́n mọ́ ọrùn rẹ.

Nígbà ìwọ ń rìn, wọn yóò ṣe amọ̀rẹ;

nígbà ìwọ sùn, wọn yóò máa ṣe olùṣọ́ rẹ;

nígbà o , wọn yóò sọ̀rọ̀.

Nítorí àwọn àṣẹ yìí jẹ́ fìtílà,

̀kọ́ yìí jẹ́ ìmọ́lẹ̀,

àti ìtọ́nisọ́ti ìbáwí

ni ̀ìyè.

Gba ọgbọ́n, gba òye,

ṣe gbàgbé ̀rọ̀ mi tàbí o yẹsẹ̀ kúrò nínú rẹ̀.

ṣe kọ ọgbọ́n sílẹ̀, yóò dáàbò ́,

fẹ́ràn rẹ̀, yóò bojútó .

Ọgbọ́n ni ó ga ; nítorí náà gba ọgbọ́n.

ó tilẹ̀ gbogbo ohun o , gba òye.

Gbé e ga, yóò gbé ga

dìrọ̀ mọ́ ọn, yóò bu iyì fún .

Di ̀kọ́ , ṣe jẹ́ ó lọ;

tọ́u rẹ̀ dáradára nítorí òun ni ìyè rẹ.

ṣe gbé ẹsẹ̀ rẹ ojú ọnà àwọn ènìyàn búburú

tàbí o rìn ̀àwọn ẹni ibi.

Ju gbogbo nǹkan tókù lọ, pa ọkàn rẹ mọ́,

nítorí òun ni orísun ìyè.

àrékérekè kúrò ẹnu rẹ;

jẹ́ ̀rọ̀ ìsọkúsọ jìnnà réré ẹnu rẹ.

Jẹ́ ojú rẹ máa wo iwájú,

jẹ́ ìwo ojú rẹ máa wo ̀kánkán iwájú rẹ á.

Kíyèsi ìrìn ẹsẹ̀ rẹ

rìn àwọn ̀ó dára nìkan.

ṣe sọ́tùn ún tàbí sósì;

pa ẹsẹ̀ rẹ mọ́ kúrò nínú ibi.

Ìkọ́ni ọlọ́gbọ́n jẹ́ orísun ìyè,

ń ènìyàn padà kúrò nínú ìdẹ̀kùn ikú.

"Ìbẹ̀Olúwa ni ìbẹ̀rẹ̀ ọgbọ́n,

ìmọ̀ nípa Ẹni Mímọ́ ni òye.

Maskili ti Asafu.

̀yin ènìyàn mi, gbọ́ ̀kọ́ mi;

tẹ́rẹ ̀rọ̀ ẹnu mi.

Èmi ó la ẹnu mi òwe,

èmi o sọ ohun ìkọ̀kọ̀, ohun ti ọjọ́ pípẹ́;

ohun a ti gbọ́ a ti mọ̀,

ohun àwọn baba wa ti sọ fún wa.

Àwa yóò pa wọ́n mọ́

kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọmọ,

fífi ìyìn Olúwa, àti ipa rẹ̀

àti iṣẹ́ ìyanu ti ṣe hàn

fún ìran ń bọ̀.

ìgbẹ̀yìn, gbogbo ìran náà ; àwọn ìran ó tẹ̀wọn sin Olúwa nítorí wọn mọ Olúwa, bẹ́̀ ni wọn mọ ohun Olúwa ṣe fún Israẹli.

Fidelidade no ensino

Quem ensina com fidelidade merece dupla honra. Cuidado com doutrinas falsas — permaneçam na doutrina de Cristo.

Àwọn alàgbà ti ó ṣe àkóso dáradára ni a yẹ ọlá ìlọ́po méjì, pẹ̀lúpẹ̀àwọn ti ó ṣe làálàá ni ̀rọ̀ àti ni kíkọ́ni. Nítorí Ìwé Mímọ́ , "Ìwọ gbọdọ̀ di màlúù ti ń tẹ ọkà lẹ́nu," àti , "̀alágbàṣe tọ́ i."

kúrò nínú ̀rọ̀ asán, nítorí tiwọn máa síwájú nínú àìwà-bí-Ọlọ́run. ̀rọ̀ wọn yóò máa fẹ́ egbò kíkẹ̀; nínú àwọn ẹni Himeneu àti Filetu ;

Olúkúlùkù ẹni ó ń òfin si dúró nínú ̀kọ́ Kristi, mọ Ọlọ́run. Ẹni ó dúró nínú ̀kọ́, òun ni ó mọ Baba àti Ọmọ.

Jesu kọ́ àwọn ènìyàn

Nígbà àjọ àárín; Jesu gòkè lọ tẹmpili ó ń kọ́ni. Ẹnu ya àwọn Júù, wọ́n , "Ọkùnrin yìí ti ṣe mọ ìwé, nígbà kọ́ ̀kọ́?"

Jesu dáhùn, ó , "̀kọ́ mi í ṣe tèmi, ṣe ti ẹni ó rán mi. ẹnikẹ́ni fẹ́ láti ṣe ìfẹ́ rẹ̀ yóò mọ̀ ti ̀kọ́ náà, ìbá ṣe ti Ọlọ́run, tàbí èmi sọ ti ara mi. Ẹni ń sọ ti ara rẹ̀ ń ògo ara rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹni ń ògo ẹni ó rán an, òun ni olóòtítọ́, àìṣòdodo nínú rẹ̀.

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-