Publicidade

Salmos 78

Maskili ti Asafu.

1 ̀yin ènìyàn mi, gbọ́ ̀kọ́ mi;

tẹ́rẹ ̀rọ̀ ẹnu mi.

2 Èmi ó la ẹnu mi òwe,

èmi o sọ ohun ìkọ̀kọ̀, ohun ti ọjọ́ pípẹ́;

3 ohun a ti gbọ́ a ti mọ̀,

ohun àwọn baba wa ti sọ fún wa.

4 Àwa yóò pa wọ́n mọ́

kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọmọ,

fífi ìyìn Olúwa, àti ipa rẹ̀

àti iṣẹ́ ìyanu ti ṣe hàn

fún ìran ń bọ̀.

5 Ó gbé ̀kalẹ̀ Jakọbu

o fìdí àṣẹ múlẹ̀ Israẹli,

èyí ó pàṣẹ fún àwọn baba ńlá wa

láti kọ́ àwọn ọmọ wọn,

6 nítorí náà, àwọn ìran ń bọ̀ yóò mọ̀ wọ́n

bẹ́̀ ni àwọn ọmọ a ì

yóò dìde wọn yóò sọ fún àwọn ọmọ wọn.

7 Nígbà náà ni wọ́n ò fi ìgbẹ́kẹ̀wọn sínú Ọlọ́run

wọn gbàgbé iṣẹ́ Ọlọ́run

ṣùgbọ́n wọn ó pa àṣẹ rẹ̀ mọ́.

8 wọn ó ṣe dàbí àwọn baba ńlá wọn,

ìran alágídí àti ọlọ́tẹ̀,

ìran ọkàn wọn ṣọ òtítọ́ si olóore,

àti ̀ẹni Ọlọ́run dúró ṣinṣin.

9 Àwọn ọkùnrin Efraimu, ó mọ́ wọ́n ọrun,

wọ́n yípadà ọjọ́ ogun

10 Wọn pa májẹ̀Ọlọ́run mọ́

wọn kọ̀ láti máa gbé nínú òfin rẹ̀.

11 Wọ́n gbàgbé ohun ó ti ṣe,

àwọn ìyanu ó ti fihàn wọ́n.

12 Ó ṣe ìyanu níwájú àwọn baba wọn ilẹ̀ Ejibiti, agbègbè Ṣoani.

13 Ó pín òkun , ó wọn kọjá

Ó omi náà dúró bi odi gíga.

14 ̀sán, ó fi ìkùùkuu àwọsánmọ̀ ṣe amọ̀wọn

àti gbogbo òru pẹ̀ìmọ́lẹ̀ iná.

15 Ó sán àpáta aginjù

ó fún wọn omi mímu lọ́pọ̀lọ́pọ̀

ẹni láti inú ibú .

16 Ó ìṣàn omi jáde láti inú àpáta

omi ṣíṣàn sílẹ̀ gẹ́gẹ́ odò.

17 Wọ́n tún tẹ̀síwájú láti dẹ́ṣẹ̀ i

ìṣọ̀tẹ̀ ̀gá-ògo aginjù.

18 Wọ́n mọ̀ ́n mọ̀ dán Ọlọ́run

nípa bíbéèrè fún oúnjẹ wọn bẹ̀bẹ̀ fún.

19 Wọ́n sọ̀rọ̀-òdì Ọlọ́run,

"Ọlọ́run ha tẹ́ tábìlì aginjù?

20 Nígbà ó lu àpáta, omi jáde,

odò sàn lọ́pọ̀lọ́pọ̀

ṣùgbọ́n òun ha fún wa lóúnjẹ

ó ha le pèsè ẹran fún àwọn ènìyàn rẹ̀?"

21 Nígbà Olúwa gbọ́ wọn, ó bínú gidigidi;

iná rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ Jakọbu,

ìbínú rẹ̀ Israẹli,

22 nítorí wọn gba Ọlọ́run gbọ́,

wọn gbẹ́kẹ̀ìgbàlà rẹ̀.

23 Síbẹ̀ ó pàṣẹ fún ìràwọ̀ ojú ̀run,

ó ṣí ìlẹ̀kùn ̀run sílẹ̀;

24 Ó rọ manna fún àwọn ènìyàn láti jẹ,

ó fún wọn ọkà láti ̀run.

25 Àwọn ènìyàn jẹ oúnjẹ àwọn angẹli;

Ó fún wọn oúnjẹ àjẹyó,

26 Ó afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn láti ̀run

ó afẹ́fẹ́ gúúsù nípa agbára rẹ̀.

27 Ó rọ òjò ẹran sílẹ̀ sórí wọn erùpẹ̀ ilẹ̀,

àti ẹyẹ abìyẹ́ gẹ́gẹ́ iyanrìn etí òkun

28 Ó jẹ́ wọn jáde ibùdó wọn,

yíká àgọ́ wọn.

29 Wọ́n jẹ, wọ́n jọjọ

nítorí ó ti fún wọn ohun wọn fìtara bẹ̀bẹ̀ fún.

30 Ṣùgbọ́n wọn kúrò nínú oúnjẹ wọn fìtara bẹ̀bẹ̀ fún,

nígbà oúnjẹ wọn ẹnu wọn,

31 ìbínú Ọlọ́run dìde wọn

ó pa àwọn ó jùlọ nínú wọn,

ó lu àwọn ̀dọ́mọkùnrin Israẹli bolẹ̀.

32 Nínú gbogbo ìwọ̀nyí, wọ́n ń dẹ́ṣẹ̀ síwájú;

nínú gbogbo iṣẹ́ ìyanu rẹ̀, wọ́n gbàgbọ́.

33 O fi òpin ayé wọn nínú asán

àti ọdún wọn nínú ìpayà.

34 Nígbàkígbà Ọlọ́run pa wọ́n,

wọn yóò a kiri;

wọn yóò fi ìtara yípadà i.

35 Wọ́n rántí Ọlọ́run àpáta wọn;

Ọlọ́run ̀gá-ògo jùlọ ni olùràpadà àpáta wọn.

36 Ṣùgbọ́n nígbà náà ni wọ́n yóò pọ́n ọn pẹ̀ẹnu wọ́n

wọ́n fi ahọ́n wọ́n purọ́ fún un;

37 ọkàn wọn sòtítọ́ i,

wọn jẹ́ olódodo májẹ̀rẹ̀.

38 Síbẹ̀ ó ṣàánú;

ó dárí àìṣedéédéé wọn

òun pa wọ́n run

nígbà púpọ̀ ń ìbínú rẹ̀ padà

ru ìbínú rẹ̀ sókè

39 Ó rántí ẹlẹ́ran ara ni wọ́n,

afẹ́fẹ́ ń kọjá padà.

40 Nígbà gbogbo wọn ń ṣọ̀tẹ̀ i aginjù

wọn un bínú nínú ilẹ̀ ó di ahoro!

41 Síwájú àti síwájú wọ́n dán Ọlọ́run ;

wọ́n ẹni mímọ́ Israẹli bínú.

42 Wọ́n rántí agbára rẹ̀:

ọjọ́ ó wọ́n padà lọ́wọ́ àwọn aninilára,

43 ọjọ́ ó fi iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ hàn Ejibiti,

àti iṣẹ́ àmì rẹ̀ ni ẹkùn Ṣoani

44 Ó sọ omi wọn di ̀jẹ̀;

wọn mu láti odò wọn.

45 Ó rán ̀wọ́ eṣinṣin láti pa wọ́n run,

àti ̀pọ̀lọ́ ó wọn jẹun.

46 Ó fi ọkà wọn fún láńtata,

àwọn ìre oko wọn fún eṣú.

47 Ó fi yìnyín ba àjàrà wọn jẹ́

ó èso sikamore wọn jẹ́.

48 Ó fi ohun ̀sìn wọn fún yìnyín,

agbo ẹran wọn fún mọ̀nàmọ́.

49 Ó kíkorò ìbínú rẹ̀ wọn lára,

ìrunú àti ìkáàánú, àti ìpọ́njú,

nípa rírán angẹli apanirun wọn.

50 Ó pèsè ipa fún ìbínú rẹ̀,

òun gbà wọ́n lọ́wọ́ ikú,

ṣùgbọ́n ó fi ̀wọ́n fún àjàkálẹ̀-ààrùn.

51 Ó kọlu àwọn àkọ́ọmọ ọkùnrin Ejibiti,

olórí agbára wọn nínú àgọ́ Hamu.

52 Ṣùgbọ́n ó àwọn ènìyàn rẹ̀ jáde ̀wọ́ ẹran;

ó ṣọ́ wọn gẹ́gẹ́ àgùntàn nínú aginjù.

53 Ó dáàbò wọ́n dáradára, nítorí náà ni ̀ṣe wọ́n

ṣùgbọ́n òkun padé mọ́ àwọn ̀wọn.

54 Bákan náà ni ó wọn etí ilẹ̀ mímọ́ rẹ̀

òkè ọwọ́ ̀tún rẹ̀ ti gbà

55 Ó kèfèrí jáde níwájú wọn

ó fi títa okùn pín ilẹ̀ náà fún wọn gẹ́gẹ́ ilẹ̀ ìní;

ó àwọn ̀Israẹli jókòó ilẹ̀ wọn.

56 Ṣùgbọ́n wọn dán Ọlọ́run

wọn ṣọ̀tẹ̀ ̀gá-ògo;

wọn pa àṣẹ rẹ̀ mọ́.

57 Ṣùgbọ́n wọ́n yípadà,

wọn jẹ́ aláìṣòdodo gẹ́gẹ́ àwọn baba wọn

wọ́n pẹ̀yìndà apákan ọrun ̀tàn.

58 Wọ́n i nínú pẹ̀ibi gíga wọn;

wọn owú rẹ̀ sókè nípa òrìṣà wọn.

59 Nígbà Ọlọ́run gbọ́ wọn,

inú i gidigidi;

ó kọ Israẹli pátápátá.

60 Ó kọ àgọ́ Ṣilo sílẹ̀,

àgọ́ ó ti gbé kalẹ̀ láàrín àwọn ènìyàn.

61 Ó rán àpótí ̀, agbára rẹ̀ lọ ìgbèkùn,

dídán ògo rẹ̀ lọ ọwọ́ àwọn ̀.

62 Ó fi àwọn ènìyàn rẹ̀ idà lọ́wọ́,

ó bínú àwọn ohun ìní rẹ̀.

63 Iná run àwọn ̀dọ́mọkùnrin wọn,

àwọn ọmọbìnrin wọn orin ìgbéyàwó:

64 àfi àlùfáà wọn fún idà,

àwọn opó wọn le è sọkún.

65 Olúwa gẹ́gẹ́ ẹni ojú oorun,

gẹ́gẹ́ ọkùnrin ti i kúrò nínú ìraníyè ọtí.

66 Ó kọlu àwọn ̀rẹ̀ padà;

ó fi wọn sínú ìtìjú ayérayé.

67 Nígbà náà ni ó kọ́ àgọ́ Josẹfu,

yan ̀Efraimu,

68 ṣùgbọ́n ó yan ̀Juda,

òkè Sioni, èyí ó fẹ́ràn.

69 Ó kọ́ ibi mímọ́ rẹ̀, ibi gíga,

gẹ́gẹ́ ayé ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ títí láé.

70 Ó yan Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀

ó láti inú àwọn agbo ẹran;

71 Ó un jáde nínú ìtọ́àgùntàn

láti jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn àwọn ènìyàn rẹ̀ Jakọbu

àti Israẹli ogún un rẹ̀.

72 Dafidi ṣọ́ wọn pẹ̀òtítọ́ inú ọkàn;

pẹ̀ọwọ́ òye ni ó fi darí wọn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-