Publicidade

Deuteronômio 6

Fẹ́ràn Olúwa Ọlọ́run rẹ

1 Wọ̀nyí ni àwọn àṣẹ, ìlànà àti òfin Olúwa Ọlọ́run yín pàṣẹ fún mi láti kọ́ yín kíyèsi i, ilẹ̀ náà ó ni lẹ́yìn kọjá a Jordani. 2 ̀yin, àwọn ọmọ yín àti àwọn ọmọ wọn, lẹ́yìn wọn à bẹ̀Olúwa Ọlọ́run yín, gbogbo ìgbà láyé, nípa pípa àwọn ìlànà àti àṣẹ rẹ̀ mo fún un yín mọ́, à pẹ́ lórí ilẹ̀. 3 Gbọ́ ìwọ Israẹli, o ṣọ́ra láti gbọ́rọ̀, ó à dára fún , o à gbilẹ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ ilẹ̀ ń sàn fún wàrà àti fún oyin, gẹ́gẹ́ Olúwa Ọlọ́run àwọn baba rẹ ti ṣèlérí fún .

4 Gbọ́ ìwọ Israẹli, Olúwa Ọlọ́run wa, Olúwa kan ni. 5 Fẹ́ràn Olúwa Ọlọ́run rẹ pẹ̀gbogbo àyà rẹ àti gbogbo ọkàn rẹ, àti gbogbo agbára rẹ. 6 Àwọn àṣẹ mo fún un yín lónìí gbọdọ̀ máa lóókan àyà yín. 7 fi kọ́ àwọn ọmọ yín gidigidi. jókòó nínú ilé, jíròrò nípa wọn, àti nígbà ń rìn ojú ̀, dùbúlẹ̀ àti nígbà dìde. 8 so wọ́n ọwọ́ yín fún àmì, so ó mọ́ iwájú orí yín. 9 ìwọ ó kọ wọ́n sára òpó ilé rẹ̀, àti ara ìlẹ̀kùn ̀òde rẹ.

10 Nígbà Olúwa Ọlọ́run yín yín ilẹ̀ náà ó ti búra fún àwọn baba yín, fún Abrahamu, Isaaki, àti Jakọbu láti fi fún un yín, ilẹ̀ ó kún fún àwọn ìlú ńlá ńlá í ṣe ̀yin kọ́ , 11 àwọn ilé ó kún fún gbogbo ohun mèremère í ṣe ̀yin wọ́n, àwọn kànga gbẹ́, àti àwọn ọgbà àjàrà àti èso olifi í ṣe ̀yin gbìn wọ́n. Nígbà jẹ , 12 ṣọ́ra ṣe gbàgbé Olúwa, o un yín jáde láti Ejibiti , kúrò oko ẹrú.

13 Bẹ̀Olúwa Ọlọ́run rẹ, Òun nìkan ni o máa sìn, búra orúkọ rẹ̀ nìkan. 14 ̀yin gbọdọ̀ tẹ̀ọlọ́run mìíràn: ọlọ́run àwọn ó i yín ; 15 torí Olúwa Ọlọ́run yín ó láàrín yín, Ọlọ́run owú ni, ìbínú rẹ̀ yóò run yín kúrò ilẹ̀ náà. 16 ̀yin gbọdọ̀ dán Olúwa Ọlọ́run yín ̀yin ti dán Massa. 17 i dájú ̀ ń pa àwọn òfin Olúwa Ọlọ́run yín mọ́ àti àwọn àṣẹ àti àwọn ìlànà ó ti fún un yín. 18 ṣe èyí ó dára ó tọ́ lójú Olúwa, ó à dára fún un yín, ̀yin à lọ láti gba ilẹ̀ dáradára náà Ọlọ́run ti fi ìbúra ṣèlérí fún àwọn baba ńlá a yín. 19 ̀yin yóò ti àwọn ̀yín jáde níwájú u yín Olúwa ti ṣèlérí.

20 ọjọ́ iwájú, ọmọ rẹ béèrè , "ni ìtumọ̀ àwọn àṣẹ, ìlànà àti òfin wọ̀nyí Olúwa Ọlọ́run wa ti pàṣẹ fún ?" 21 Sọ fún un : "Ẹrú Farao ilẹ̀ Ejibiti ni tẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n Olúwa fi ọwọ́ agbára ńlá yọ jáde lóko ẹrú Ejibiti. 22 Lójú wa ni Olúwa ṣe iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu: ó lágbára ó ba ni lẹ́: lórí Ejibiti àti Farao, àti gbogbo ènìyàn rẹ̀. 23 Ṣùgbọ́n ó wa jáde láti ibẹ̀ láti wa wọ inú àti láti fún wa ilẹ̀ ó ti búra fún àwọn baba ńlá wa. 24 Olúwa pàṣẹ fún wa láti ṣe ìgbọ́ràn gbogbo ìlànà wọ̀nyí, láti bẹ̀Olúwa Ọlọ́run wa, ó ba à máa dára fún wa nígbà gbogbo, a láyé, a ṣe títí di òní. 25 a ṣọ́ra láti pa gbogbo òfin wọ̀nyí mọ́ níwájú Olúwa Ọlọ́run wa, ó ti pàṣẹ fún wa, èyí ni yóò máa jẹ́ òdodo wa."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-