Publicidade

Provérbios 6

Ìkìlọ̀ láti ṣọ́ra fún ìwà òmùgọ̀

1 Ọmọ mi, ìwọ ṣe onídùúró fún aládùúgbò rẹ,

ìwọ jẹ́ ̀jẹ́ fún àjèjì ènìyàn,

2 a ti fi ̀rọ̀ ó sọ dẹkùn ,

̀rọ̀ ẹnu rẹ ti pàkúté.

3 Nígbà náà, ṣe èyí, ìwọ ọmọ mi, láti gba ara rẹ

níwọ̀n o ti ṣọ́wọ́ aládùúgbò rẹ:

lọ o rẹ ara rẹ sílẹ̀;

bẹ aládùúgbò rẹ dáradára.

4 ṣe jẹ́ oorun ó kùn ́,

tàbí o tilẹ̀ tòògbé rárá.

5 Gba ara rẹ sílẹ̀, abo èsúró kúrò lọ́wọ́ ọdẹ,

ẹyẹ kúrò nínú okùn àwọn pẹyẹpẹyẹ.

6 Tọ èèrà lọ, ìwọ ̀lẹ;

kíyèsi ìṣe rẹ̀, o gbọ́n!

7 olùdarí,

alábojútó tàbí ọba,

8 síbẹ̀, a ìpèsè rẹ̀ jọ àsìkò òjò

yóò oúnjẹ rẹ̀ jọ àsìkò ìkórè.

9 Yóò ti pẹ́ ìwọ yóò dùbúlẹ̀, ìwọ ̀lẹ?

Nígbà wo ni ìwọ yóò kúrò lójú oorun rẹ?

10 Oorun díẹ̀, òògbé díẹ̀,

ìkáwọ́gbera láti sinmi díẹ̀.

11 Òsì yóò sórí rẹ ìgárá ọlọ́ṣà

àti àìní adigunjalè.

12 Ènìyànkénìyàn àti ènìyàn búburú,

ń ru ẹnu àrékérekè káàkiri,

13 ó ń ṣẹ́pàkòpàkò,

ó ń fi ẹsẹ̀ rẹ̀ sọ̀rọ̀

ó ń fi ìka ọwọ́ rẹ̀ júwe,

14 ó ń pète búburú pẹ̀̀tàn nínú ọkàn rẹ̀

ìgbà gbogbo ni ó máa ń ìjà sílẹ̀.

15 Nítorí náà ìdààmú yóò a ìṣẹ́akàn;

yóò parun lójijì láìsí àtúnṣe.

16 Àwọn ohun mẹ́Olúwa kórìíra,

ohun méje ó jẹ́ ìríra i,

17 Ojú ìgbéraga,

ahọ́n ń parọ́

ọwọ́ ń ta ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sílẹ̀,

18 ọkàn ń pète ohun búburú,

ẹsẹ̀ ó yára láti sáré sínú ìwà ìkà,

19 ajẹ́rìí èké ń irọ́ jáde lẹ́nu

àti ènìyàn ń ìjà sílẹ̀ láàrín àwọn ọmọ ìyá kan.

Ìkìlọ̀ nítorí àgbèrè

20 Ọmọ mi, pa àṣẹ baba rẹ mọ́

ṣe kọ ̀kọ́ ìyá rẹ sílẹ̀.

21 Jẹ́ wọn nínú ọkàn rẹ láéláé

so wọ́n mọ́ ọrùn rẹ.

22 Nígbà ìwọ ń rìn, wọn yóò ṣe amọ̀rẹ;

nígbà ìwọ sùn, wọn yóò máa ṣe olùṣọ́ rẹ;

nígbà o , wọn yóò sọ̀rọ̀.

23 Nítorí àwọn àṣẹ yìí jẹ́ fìtílà,

̀kọ́ yìí jẹ́ ìmọ́lẹ̀,

àti ìtọ́nisọ́ti ìbáwí

ni ̀ìyè.

24 Yóò pa ́ mọ́ kúrò lọ́wọ́ obìnrin búburú,

kúrò lọ́wọ́ ẹnu dídùn obìnrin àjèjì.

25 ṣe ṣe ìfẹ́kúfẹ̀́ si nínú ọkàn rẹ nítorí ẹwà rẹ

tàbí o jẹ́ ó fi ojú rẹ̀ ́ mọ́ra.

26 Nítorí nípasẹ̀ àgbèrè obìnrin ni ènìyàn fi ń di oníṣù-àkàrà kan,

ṣùgbọ́n àyà ènìyàn a máa ìyè rẹ̀ dáradára.

27 Ǹjẹ́ ọkùnrin ha le è gbé iná orí itan

aṣọ rẹ̀ jóná?

28 Ǹjẹ́ ènìyàn le è máa rìn lórí iná?

ẹsẹ̀ rẹ̀ jóná?

29 Bẹ́̀ ni ẹni ń lọ sùn pẹ̀aya aláya;

ẹni ó fọwọ́ kàn án yóò lọ láìjìyà.

30 Àwọn ènìyàn í kẹ́gàn olè ó jalè

nítorí àti jẹun nígbà ebi ń pa á.

31 Síbẹ̀ ọwọ́ tẹ̀ ́, ó gbọdọ̀ san ìlọ́po méje

ó tilẹ̀ gbogbo ohun nílé .

32 Ṣùgbọ́n ẹni ń ṣe àgbèrè nírònú;

ẹnikẹ́ni ó ń ṣe bẹ́̀ ó ń pa ara rẹ̀ run ni.

33 Ìfarapa àti ìtìjú ni tirẹ̀,

̀gàn rẹ̀ yóò kúrò láéláé.

34 Nítorí owú yóò ru ìbínú ọkọ sókè,

yóò ṣàánú nígbà ó ń gbẹ̀san.

35 nígbà nǹkan kan ohun ìtánràn;

yóò kọ àbẹ̀tẹ́lẹ̀, ó ti ó pọ̀ .

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-