Publicidade

Juízes 2

Angẹli Olúwa Bokimu

1 ọjọ́ kan angẹli Olúwa dìde kúrò láti Gilgali lọ Bokimu ó , "Èmi un yín gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti , èmi síwájú yín ilẹ̀ mo ti búra láti fi fún àwọn baba ńlá yín. Èmi , Èmi yóò yẹ májẹ̀mi pẹ̀yín, 2 ̀yin gbọdọ̀ àwọn ènìyàn ilẹ̀ májẹ̀àlàáfíà, ṣùgbọ́n ̀yin yóò pẹpẹ ibi ìsin òrìṣà wọn lulẹ̀.’ Síbẹ̀ ̀yin ṣe àìgbọ́ràn mi. Èéṣe ̀yin fi ṣe èyí? 3 báyìí, èmi fún un yín , èmi yóò àwọn ènìyàn jáde kúrò níwájú yín; ṣùgbọ́n wọn yóò jẹ́ ̀gún ìhà yín, àwọn òrìṣà wọn yóò jẹ́ ìdánwò fún un yín."

4 angẹli Olúwa ti sọ gbogbo ̀rọ̀ wọ̀nyí fún àwọn ará Israẹli tan, àwọn ènìyàn náà gbé ohùn wọn sókè wọ́n sọkún kíkorò, 5 wọ́n pe orúkọ ibẹ̀ Bokimu (ibi àwọn ènìyàn ti sọkún). Wọ́n ẹbọ Olúwa níbẹ̀.

Àìgbọ́ràn àti ìkùnà ogun

6 Lẹ́yìn Joṣua ti àwọn ènìyàn Israẹli , àwọn ̀Israẹli kọ̀̀kan lọ ilẹ̀ a fi fún wọn láti lọ gbà á ìní wọn. 7 Àwọn ènìyàn náà sin Olúwa gbogbo ìgbà ayé Joṣua àti gbogbo ọjọ́ àwọn àgbàgbà ó lẹ́yìn ikú rẹ̀ wọ́n gbogbo iṣẹ́ ńlá Olúwa ṣe fún Israẹli.

8 Joṣua ọmọ Nuni, ìránṣẹ́ Olúwa, ẹni àádọ́ọdún. 9 Wọ́n sìnkú rẹ̀ ààlà ilẹ̀ ìní rẹ̀ Timnati-Hereki ilẹ̀ òkè Efraimu àríwá òkè Gaaṣi.

10 ìgbẹ̀yìn, gbogbo ìran náà ; àwọn ìran ó tẹ̀wọn sin Olúwa nítorí wọn mọ Olúwa, bẹ́̀ ni wọn mọ ohun Olúwa ṣe fún Israẹli. 11 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe ohun ó burú níwájú Olúwa, wọ́n ń sin òrìṣà Baali. 12 Wọ́n kọ Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn sílẹ̀, ẹni ó wọn jáde kúrò ilẹ̀ Ejibiti, wọ́n ń tọ àwọn òrìṣà lẹ́yìn, wọ́n ń sin àwọn oríṣìíríṣìí òrìṣà àwọn ará ilẹ̀ ibi wọ́n ń gbé, wọ́n Olúwa bínú, 13 nítorí wọ́n kọ̀ Olúwa sílẹ̀ àti nítorí wọ́n ń sin Baali àti Aṣtoreti. 14 Nínú ìbínú rẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli Olúwa fi wọ́n àwọn akónisìn lọ́wọ́ ó wọn ẹrú, ó wọ́n jẹ́. Ó wọ́n fún àwọn ̀wọn ó wọn àwọn ẹni wọn le dúró láti kọ ojú ìjà . 15 Nígbàkígbà àwọn Israẹli jáde lọ ojú ogun láti , ọwọ́ Olúwa wúwo ara wọn, àwọn ̀a borí wọn, àní gẹ́gẹ́ ó ti búra fún wọn. Wọ́n nínú ìpọ́njú púpọ̀.

16 Olúwa gbé àwọn onídàájọ́ dìde ó gbà wọ́n sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ń wọn lẹ́. 17 Síbẹ̀síbẹ̀ wọn fi etí ti àwọn onídàájọ́ wọn, ṣùgbọ́n wọ́n ṣe àgbèrè, wọ́n ń sin òrìṣà. Wọn dàbí àwọn baba wọn, kíákíá ni wọ́n yípadà kúrò lọ́àwọn baba wọ́n ń tọ̀, ̀ìgbọ́ràn àwọn òfin Olúwa. 18 Nígbà ìgbà Olúwa gbé onídàájọ́ dìde fún wọn, Olúwa máa ń pẹ̀onídàájọ́ náà, a gbà wọ́n kúrò ọwọ́ àwọn ̀wọn ìwọ̀n ìgbà onídàájọ́ náà láààyè nítorí àánú Olúwa ara wọn, nígbà wọ́n ìrora lábẹ́ àwọn ń tẹrí wọn ba, ń fi ìyà jẹ wọ́n. 19 Ṣùgbọ́n kété onídàájọ́ ti , àwọn ènìyàn náà a tún padà ̀ìbàjẹ́ àní ju ti àwọn baba wọn lọ, wọn a tẹ̀òrìṣà, wọ́n ń sìn wọ́n, wọn a foríbalẹ̀ fún wọn, wọ́n kọ̀ láti yàgò kúrò ̀ibi wọn àti agídí ọkàn wọn.

20 Ìbínú Olúwa yóò tún ru Israẹli a , "Nítorí orílẹ̀-èdè yìí ti yẹ májẹ̀mo fi lélẹ̀ fún àwọn baba ńlá wọn, wọn fetí mi, 21 Èmi yóò ̀kankan nínú àwọn orílẹ̀-èdè Joṣua fi sílẹ̀ nígbà ó jáde. 22 Ṣùgbọ́n dípò bẹ́̀ èmi yóò lo àwọn orílẹ̀-èdè yìí láti fi dán Israẹli , láti mọ̀ bóyá wọ́n yóò pa ̀Olúwa mọ́ àti bóyá wọn ó rìn nínú rẹ̀ àwọn baba ńlá wọn ti rìn." 23 Nítorí náà Olúwa fi àwọn orílẹ̀-èdè náà sílẹ̀ ilẹ̀ náà wọn jáde, tàbí ó jẹ́ àwọn Israẹli pa wọ́n run, bẹ́̀ fi wọ́n Joṣua lọ́wọ́.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-