Publicidade

Esdras 8

Olórí àwọn ìdílé ó padà pẹ̀Esra

1 Wọ̀nyí ni àwọn olórí ìdílé àti àwọn ó fi orúkọ sílẹ̀ pẹ̀àwọn wọn gòkè pẹ̀mi láti Babeli àkókò ìjọba Artasasta ọba:

2 nínú àwọn ọmọ Finehasi:

Gerṣomu;

nínú àwọn ọmọ Itamari:

Daniẹli;

nínú àwọn ọmọ Dafidi:

Hattusi, 3 nínú àwọn ọmọ Ṣekaniah;

nínú àwọn ọmọ Paroṣi:

Sekariah, àti àádọ́jọ ọkùnrin fi orúkọ sílẹ̀ pẹ̀rẹ;

4 nínú àwọn ọmọ Pahati-Moabu:

Elihoenai ọmọ Serahiah àti àwọn igba ọkùnrin pẹ̀rẹ̀;

5 nínú àwọn ọmọ Sattu:

Ṣekaniah ọmọ Jahasieli àti àwọn ̀́dúnrún (300) ọkùnrin pẹ̀rẹ̀;

6 nínú àwọn ọmọ Adini:

Ebedi ọmọ Jonatani, àti àádọ́ta ọkùnrin pẹ̀rẹ̀;

7 nínú àwọn ọmọ Elamu:

Jeṣaiah ọmọ Ataliah àwọn àádọ́rin ọkùnrin pẹ̀rẹ̀;

8 nínú àwọn ọmọ Ṣefatia:

Sebadiah ọmọ Mikaeli, àti ọgọ́rin ọkùnrin pẹ̀rẹ̀;

9 nínú àwọn ọmọ Joabu:

Obadiah ọmọ Jehieli àti ogún ó nígba ó dín méjì (218) ọkùnrin pẹ̀rẹ̀;

10 nínú àwọn ọmọ Bani:

Ṣelomiti ọmọ Josafiah, àti ọgọ́jọ ọkùnrin pẹ̀rẹ̀;

11 nínú àwọn ọmọ Bebai:

Sekariah ọmọ Bebai àti ọkùnrin méjìdínlọ́gbọ̀n pẹ̀rẹ̀;

12 nínú àwọn ọmọ Asgadi:

Johanani ọmọ Hakatani, àti àádọ́ọkùnrin pẹ̀rẹ̀;

13 nínú àwọn ọmọ Adonikami:

àwọn ti ó gbẹ̀yìn, orúkọ wọn ń jẹ́ Elifaleti, Jeieli àti Ṣemaiah, àti ọgọ́ta ọkùnrin pẹ̀wọn;

14 nínú àwọn ọmọ Bigfai:

Uttai àti Sakkuri, àti àádọ́rin ọkùnrin pẹ̀wọn.

Ìpadà Jerusalẹmu

15 Èmi wọn jọ pọ̀ si etí odò ti ń sàn lọ Ahafa, a pàgọ́ síbẹ̀ fún odidi ọjọ́ mẹ́ta, nígbà ti mo wo àárín àwọn ènìyàn àti àárín àwọn àlùfáà, ń ọmọ Lefi kankan níbẹ̀. 16 Nígbà náà ni mo pe Elieseri, Arieli, Ṣemaiah, Elnatani, Jaribi, Elnatani, Natani, Sekariah, àti Meṣullamu, wọ́n jẹ́ olórí, àti Joiaribu àti Elnatani wọ́n jẹ́ onímọ̀ ìjìnlẹ̀, 17 mo rán wọn àwọn ti àṣẹ ̀dọ̀ Iddo, ó jẹ́ olórí ibi ti a ń ni Kasifia, mo sọ fún wọn ohun wọn yóò fun Iddo àti àwọn Lefi arákùnrin rẹ̀, wọ́n jẹ́ òṣìṣẹ́ tẹmpili Kasifia , wọn àwọn ìránṣẹ́ ̀dọ̀ wa fún ilé Ọlọ́run wa. 18 Nítorí ọwọ́ àánú Ọlọ́run wa lára wa, wọ́n Ṣerebiah fún wa, ẹni ó kún ojú òsùwọ̀n láti ìran Mahili, ọmọ Lefi, ọmọ Israẹli, àti àwọn ọmọ Ṣerebiah àti àwọn arákùnrin rẹ̀, wọ́n jẹ́ ọkùnrin méjìdínlógún. 19 Àti Haṣabiah, pẹ̀Jeṣaiah láti ìran Merari, pẹ̀àwọn arákùnrin rẹ àti àwọn ọmọ wọ́n jẹ́ ogún ọkùnrin. 20 Wọ́n tún ogún nígba (220) àwọn òṣìṣẹ́ tẹmpili àwọn ènìyàn Dafidi àti àwọn ìjòyè rẹ̀ gbé kalẹ̀ láti ran àwọn ọmọ Lefi lọ́wọ́. Gbogbo wọn ni a ṣe àkọsílẹ̀ orúkọ wọn.

21 Níbẹ̀, ̀odò Ahafa, mo kéde àwẹ̀, a ba à le rẹ ara wa sílẹ̀ níwájú Ọlọ́run, a béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ fún ìrìnàjò àìléwu fún wa àti àwọn ọmọ wa àti fún gbogbo ohun ìní wa. 22 Mo tijú láti béèrè lọ́wọ́ ọba fún àwọn jagunjagun orí ilẹ̀, àti ti orí ẹṣin láti dáàbò kúrò lọ́wọ́ àwọn ̀̀wa, nítorí àti sọ fún ọba , "Ọwọ́ àánú Ọlọ́run ara gbogbo ẹni ó gbé ojú sókè i, ṣùgbọ́n ìbínú ńlá rẹ lórí ẹni kọ̀ ́ sílẹ̀." 23 Bẹ́̀ ni a gbààwẹ̀, a bẹ̀bẹ̀ fún èyí lọ́dọ̀ Ọlọ́run wa, òun gbọ́ àdúrà wa.

24 Nígbà náà ni mo ya àwọn àlùfáà jẹ́ aṣáájú méjìlá sọ́tọ̀, pẹ̀Ṣerebiah, Haṣabiah àti mẹ́wàá lára àwọn arákùnrin wọn, 25 mo fi òsùwọ̀n wọn ọrẹ fàdákà àti wúrà àti àwọn ohun èlò ọba, àti ti àwọn ìgbìmọ̀, àti ti àwọn ìjòyè, àti ti gbogbo ọmọ Israẹli ó níbẹ̀, wọ́n gbe sílẹ̀ fún ilé Ọlọ́run wa. 26 Mo fi òsùwọ̀n wọn ẹgbẹ̀ta láàádọ́ta (650) tálẹ́ǹtì fàdákà, àti ohun èlò fàdákà ó wọn ọgọ́rùn-ún tálẹ́ǹtì, ọgọ́rùn-ún tálẹ́ǹtì wúrà, 27 ogún ago wúrà iye rẹ̀ ẹgbẹ̀rún (1,000) dariki, àti ohun èlò idẹ dáradára méjì ti ó ni iye lórí i wúrà.

28 Mo fún wọn , "̀yin àti àwọn ohun èlò wọ̀nyí ni a ti mímọ́ fún Olúwa. Fàdákà àti wúrà jẹ́ ọrẹ àtinúwá Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín. 29 máa tọ́wọn dáradára títí ̀yin yóò fi fi òsùwọ̀n wọ̀n wọ́n jáde kúrò ni ilé Olúwa ni Jerusalẹmu iwájú àwọn aṣáájú, àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, àti iwájú olórí ìdílé gbogbo ni Israẹli." 30 Nígbà náà ni àwọn àlùfáà àti àwọn Lefi gba fàdákà àti wúrà àti àwọn ohun èlò mímọ́ a ti wọ̀n jáde fún kíkó lọ ilé Ọlọ́run wa Jerusalẹmu.

31 ọjọ́ kejìlá oṣù kìn-ín-ní ni a gbéra kúrò ̀odò Ahafa láti lọ Jerusalẹmu. Ọwọ́ Ọlọ́run wa lára wa, ó dáàbò kúrò lọ́wọ́ àwọn ̀àti àwọn adigunjalè ̀wa. 32 Bẹ́̀ ni a gúnlẹ̀ Jerusalẹmu, níbi a ti sinmi fún ọjọ́ mẹ́ta.

33 ọjọ́ kẹrin, a wọn ohun èlò fàdákà àti wúrà àti àwọn ohun èlò mímọ àlùfáà Meremoti ọmọ Uriah lọ́wọ́, láti inú ilé Ọlọ́run wa, Eleasari ọmọ Finehasi pẹ̀rẹ̀, bẹ́̀ ni àwọn ọmọ Lefi; Josabadi ọmọ Jeṣua àti Noadiah ọmọ Binnui níbẹ̀ pẹ̀. 34 Gbogbo nǹkan ni a , a wọ̀n, gbogbo iye ìwọ̀n ni a ṣe àkọsílẹ̀ rẹ̀ sínú ìwé ìgbà náà.

35 Nígbà náà ni àwọn ìgbèkùn ó ti padà láti ilẹ̀ àjèjì ẹbọ sísun Ọlọ́run Israẹli: akọ màlúù méjìlá fún gbogbo Israẹli, àgbò mẹ́rìndínlọ́gọ́rùn-ún, ̀dọ́-àgùntàn mẹ́tàdínlọ́gọ́rin, àti òbúkọ méjìlá fún ẹbọ ̀ṣẹ̀. Gbogbo èyí jẹ́ ẹbọ sísun Olúwa. 36 Wọ́n jíṣẹ́ àṣẹ ọba fún àwọn ìjòyè àti àwọn baálẹ̀ agbègbè Eufurate, wọ́n ṣe ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ènìyàn àti ilé Ọlọ́run.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-