Pular para o conteúdo
Publicidade

Onidajọ 13

6 Nígbà náà ni obìnrin náà tọ ọkọ rẹ̀ lọ, o sọ fún un , "Ènìyàn Ọlọ́run kan tọ̀ . Ó jọ angẹli Ọlọ́run, ó ba ènìyàn lẹ́gidigidi. Èmi béèrè ibi ó ti , òun náà sọ orúkọ rẹ̀ fún mi. 7 Ṣùgbọ́n ó sọ fún mi , Ìwọ yóò lóyún, ìwọ yóò ọmọkùnrin kan, fún ìdí èyí, ṣe mu wáìnì tàbí àwọn ọtí líle mìíràn bẹ́̀ ni ìwọ ṣe jẹ ohunkóhun í ṣe aláìmọ́, nítorí Nasiri Ọlọ́run ni ọmọ náà yóò jẹ́ láti ọjọ́ ìbí rẹ̀ títí di ọjọ́ ikú rẹ̀.’ "

8 Nígbà náà ni Manoa gbàdúrà Olúwa , "Háà Olúwa, èmi bẹ̀ ́, jẹ́ ènìyàn Ọlọ́run ìwọ rán wa padà tọ̀ láti kọ́ wa àwa yóò ti ṣe tọ́ ọmọ àwa yóò náà."

Veja também