Publicidade

Juízes 14

Ìgbéyàwó Samsoni

1 Nígbà kan Samsoni gòkè lọ Timna níbẹ̀ ni ó ti ọmọbìnrin Filistini kan. 2 Nígbà ó darí , ó sọ fún àwọn òbí rẹ̀ , "Mo obìnrin Filistini kan Timna: báyìí fẹ́ fún mi aya mi."

3 Baba àti ìyá rẹ̀ dáhùn , "Ṣé obìnrin ó dára ó tẹ́ lọ́rùn àárín àwọn ìbátan rẹ, tàbí láàrín gbogbo àwọn ènìyàn wa? Ṣé ó di dandan fún láti lọ àárín àwọn Filistini aláìkọlà o fẹ́ ìyàwó?"

Ṣùgbọ́n Samsoni fún baba rẹ̀ , "Fẹ́ fún mi torí inú mi yọ́ i púpọ̀púpọ̀." 4 (Àwọn òbí rẹ̀ mọ̀ ̀dọ̀ Olúwa ni nǹkan yìí ti , ẹni ń ̀àti Filistini ; nítorí àwọn ni ń ṣe àkóso Israẹli àkókò náà.)

5 Samsoni sọ̀kalẹ̀ lọ Timna òun àti baba àti ìyá rẹ̀. wọ́n ṣe ń súnmọ́ àwọn ọgbà àjàrà ó Timna, láìròtẹ́lẹ̀, ̀dọ́ kìnnìún kan jáde síta ń ramúramù bọ̀ ̀dọ̀ rẹ̀. 6 ̀Olúwa e pẹ̀agbára bẹ́̀ ó fi fa kìnnìún náà ya pẹ̀ọwọ́ rẹ̀ lásán ẹní ya ọmọ ewúrẹ́, ṣùgbọ́n òun sọ ohun ó ṣe fún baba tàbí ìyá rẹ̀. 7 Ó lọ obìnrin náà sọ̀rọ̀, inú Samsoni yọ́ i.

8 Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, nígbà ó padà lọ láti gbé e níyàwó, ó lọ láti wo òkú kìnnìún náà. Inú rẹ̀ ni ó ti ̀pọ̀ ìṣù oyin àti oyin, 9 ó fi ọwọ́ ha jáde, ó ń jẹ ́ ó ti ń lọ. Nígbà ó ̀dọ̀ àwọn òbí rẹ̀, ó fún wọn díẹ̀, àwọn náà jẹ, ṣùgbọ́n sọ fún wọn ara òkú kìnnìún ni òun ti oyin náà.

10 Baba rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ lọ láti obìnrin náà. Samsoni ṣe àsè gẹ́gẹ́ àṣà ọkọ ìyàwó àkókò náà. 11 Nígbà ó fi ara hàn, àwọn ènìyàn náà i wọ́n fún un ọgbọ̀n àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ láti a kẹ́gbẹ́.

12 Samsoni sọ fún wọn , "jẹ́ n pa àlọ́ kan fún un yín, ̀yin fún mi ìtumọ̀ rẹ̀ láàrín ọjọ́ méje àsè yìí, tàbí ṣe àwárí àlọ́ náà èmi yóò fún un yín ọgbọ̀n aṣọ a fi òwú ̀gbọ̀ hun, àti ọgbọ̀n ìpààrọ̀ aṣọ ìyàwó. 13 Ṣùgbọ́n ̀yin le sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi, ̀yin yóò fún mi ọgbọ̀n aṣọ a fi òwú ̀gbọ̀ hun àti ọgbọ̀n ìpààrọ̀ aṣọ ìgbéyàwó."

Wọ́n dáhùn , "Sọ àlọ́ rẹ fún wa jẹ́ a gbọ́."

14 Ó dáhùn ,

"Láti inú ̀jẹun ni ohun jíjẹ ti jáde ;

láti inú alágbára ni ohun dídùn ti jáde ."

Ṣùgbọ́n fún odidi ọjọ́ mẹ́ta ni wọn fi ìtumọ̀ àlọ́ náà.

15 ọjọ́ kẹrin, wọ́n fún ìyàwó Samsoni, , "Tan ọkọ rẹ ó ṣe àlàyé àlọ́ náà fún wa, bẹ́̀ kọ́ àwa yóò sun ìwọ àti ìdílé baba rẹ̀ iná. Tàbí ṣe o ibi àsè yìí láti sọ di òtòṣì tàbí wa lẹ́ni?"

16 Nígbà náà ni ìyàwó Samsoni ṣubú e láyà, ó sọkún iwájú rẹ̀ , "O kórìíra mi! O ìfẹ́ mi nítòótọ́, o pàlọ́ fún àwọn ènìyàn mi, ìwọ sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún mi."

"Èmi ì ṣe àlàyé rẹ̀ fún baba àti ìyá mi, báwo ni èmi ó ṣe sọ ìtumọ̀ rẹ̀ fún ." 17 Fún gbogbo ọjọ́ méje wọ́n fi ṣe àsè náà ni ó fi sọkún, nítorí náà ọjọ́ keje ó sọ ìtumọ̀ àlọ́ fún un nítorí ó yọ ́ lẹ́nu ojoojúmọ́. Òun náà sọ ìtumọ̀ àlọ́ náà fún àwọn ènìyàn rẹ̀.

18 ó di àṣálẹ́ ọjọ́ keje àwọn ọkùnrin ìlú náà sọ fún un ,

"ni ó dùn ju oyin lọ?

ni ó lágbára ju kìnnìún lọ?"

Samsoni wọn lóhùn ,

"í ṣe fi ̀dọ́ abo màlúù mi kọ ilẹ̀,

̀yin mọ ìtumọ̀ àlọ́ mi."

19 Lẹ́yìn èyí, ̀Olúwa e pẹ̀agbára. Ó lọ Aṣkeloni, ó pa ọgbọ̀n nínú àwọn ọkùnrin wọn, ó gba àwọn ohun ìní wọn, ó fi àwọn aṣọ wọn fún àwọn ó sọ ìtumọ̀ àlọ́ náà. Ó padà ilé baba rẹ̀ pẹ̀ìbínú ríru. 20 Wọ́n fi ìyàwó Samsoni fún ẹlẹgbẹ́ rẹ̀, ó jẹ́ ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ rẹ̀ nígbà ìgbéyàwó rẹ̀.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-