Publicidade

Juízes 3

1 Àwọn wọ̀nyí ni àwọn orílẹ̀-èdè Olúwa fi sílẹ̀ láti dán àwọn ìran tuntun Israẹli , àwọn ìran ì ì ìrírí ogun àwọn ará Kenaani. 2 (Ó ṣe èyí láti fi kọ́ àwọn ìran Israẹli ogun níbí a ti ṣe ń jagun). 3 Àwọn ìjòyè ìlú Filistini márààrún, gbogbo àwọn ará Kenaani, àwọn ará Sidoni, àti àwọn ará Hifi ń gbé àwọn òkè Lebanoni bẹ̀rẹ̀ láti òkè Baali-Hermoni títí Lebo-Hamati. 4 A fi àwọn ènìyàn náà sílẹ̀ láti dán àwọn Israẹli bóyá wọn yóò gbọ́rọ̀ àwọn òfin Olúwa, èyí ó ti fi fún àwọn baba wọn láti ipasẹ̀ Mose.

5 Àwọn ọmọ Israẹli gbé láàrín àwọn ará Kenaani, àwọn ará Hiti àwọn ará Amori, àwọn ará Peresi, àwọn ará Hifi àti àwọn ará Jebusi. 6 Dípò wọ́n run àwọn ènìyàn wọ̀nyí, Israẹli ń fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn, wọ́n ń fi àwọn ọmọbìnrin Israẹli fún àwọn ará ilẹ̀ náà aya, wọ́n ń sin àwọn òrìṣà wọn.

Otnieli

7 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe èyí ó burú níwájú Olúwa, wọ́n gbàgbé Olúwa Ọlọ́run wọn, wọ́n ń sin Baali àti Aṣerah. 8 Ìbínú Olúwa ru Israẹli bẹ́̀ ó fi jẹ́ Kuṣani-Riṣataimu ọba Aramu-Naharaimu wọn ó ṣẹ́gun wọn, Israẹli ṣe ẹrú rẹ̀ fún ọdún mẹ́jọ. 9 Ṣùgbọ́n nígbà Israẹli kígbe Olúwa, Òun gbé olùgbàlà kan dìde fún wọn, ẹni náà ni Otnieli ọmọ Kenasi àbúrò Kalebu ó jẹ́ ọkùnrin, ẹni ó gbà wọ́n sílẹ̀. 10 ̀Olúwa e, òun ṣe ìdájọ́ Israẹli, ó síwájú wọn lọ ogun. Olúwa fi Kuṣani-Riṣataimu ọba Aramu Otnieli lọ́wọ́, ẹni ọwọ́ rẹ̀ borí Kuṣani-Riṣataimu. 11 Ilẹ̀ náà àlàáfíà fún ogójì ọdún títí Otnieli ọmọ Kenasi .

Ehudu

12 Àwọn ọmọ Israẹli tún padà ìwà ̀ṣẹ̀ wọn, wọ́n ṣe èyí ó burú iwájú Olúwa, fún ìdí iṣẹ́ búburú yìí, Olúwa fún Egloni, ọba àwọn Moabu agbára orí Israẹli. 13 Pẹ̀ìfi ọwọ́ ṣowọ́pọ̀ ogun àwọn Ammoni àti àwọn ọmọ-ogun Amaleki Egloni gbógun ti àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n gba ìlú ̀pẹ i se Jeriko. 14 Àwọn ọmọ Israẹli sin Egloni ọba Moabu fún ọdún méjìdínlógún.

15 Ṣùgbọ́n nígbà Israẹli tún pe Olúwa, Olúwa rán olùgbàlà kan wọn, Ehudu ẹni ń lo ọwọ́ òsì, ọmọ Gera ti ̀Benjamini. Àwọn ọmọ Israẹli fi ̀bùn rán Egloni ọba Moabu. 16 Ehudu rọ idà kan olójú méjì, ìgbọ̀nwọ́ kan gígùn; òun sán an abẹ́ aṣọ rẹ̀ itan rẹ̀ ̀tún. 17 Ó ọrẹ náà fún Egloni ọba Moabu, Egloni ẹni ó sanra púpọ̀. 18 Lẹ́yìn Ehudu ti fi ̀bùn náà fún ọba tan, ó rán àwọn ó ẹrú náà lọ ̀wọn. 19 Ṣùgbọ́n nígbà òun fúnra rẹ̀ ibi ère fínfín ó létí Gilgali, ó padà Egloni, ó , "Ọba, mo ̀rọ̀ àṣírí láti sọ."

Ọba , "dákẹ́!" Gbogbo àwọn ń ṣọ jáde síta kúrò ̀dọ̀ rẹ̀.

20 Ehudu lọ ̀dọ̀ rẹ̀ níbi ó ti jókòó iyàrá ìtura rẹ̀, Ehudu fún un , "Mo ̀rọ̀ kan fún láti ̀dọ̀ Ọlọ́run." ọba ti dìde orí ìtẹ́ rẹ̀, 21 Ehudu fi ọwọ́ òsì rẹ̀ yọ idà láti ibi itan ̀tún rẹ̀ ó fi gún ọba nínú ikùn rẹ̀. 22 Àti idà àti èèkù rẹ̀ wọlé ó yọ ̀yìn rẹ̀. Ehudu yọ idà náà, ̀bo idà náà. 23 Ehudu ti àwọn ìlẹ̀kùn àtì-sínú òun yàrá òkè jáde, ó sálọ.

24 Lẹ́yìn ó ti lọ àwọn ìránṣẹ́ ọba , ṣùgbọ́n nígbà wọ́n ìlẹ̀kùn yàrá òkè títì, wọ́n , "Bóyá ó ilé ìyàgbẹ́ yàrá nínú ilé." 25 Nígbà wọ́n dúró ibi ó jẹ́ ìyanu fún wọn, wọ́n kọ́kọ́rọ́, wọ́n ṣí ìlẹ̀kùn. Níbẹ̀ ni wọ́n ti Olúwa wọn ó ti ṣubú, ó ti .

26 Nígbà wọ́n dúró wọn ń retí, Ehudu ti sálọ. Ó ti gba ibi wọ́n ti ń gbẹ́ òkúta lére, ó sálọ Seira. 27 Nígbà ó ibẹ̀, ó fọn ìpè orí òkè Efraimu, àwọn ọmọ Israẹli ba sọ̀kalẹ̀ lọ láti òkè náà , òun níwájú wọn.

28 Ó fún wọn , "máa tẹ̀mi, nítorí Olúwa ti fi Moabu ̀yín yín lọ́wọ́." Wọ́n tẹ̀e, wọ́n gba ìwọdò Jordani ó lọ ilẹ̀ Moabu, wọn ò jẹ́ ẹnikẹ́ni kọjá. 29 báyìí, wọ́n ti pa ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) ọkùnrin ará Moabu wọ́n jẹ́ alágbára àti onígboyà ènìyàn, ènìyàn ó sálà. 30 ọjọ́ náà ni Israẹli ṣẹ́gun àwọn ará Moabu, ilẹ̀ náà àlàáfíà fún ọgọ́rin ọdún.

Ṣamgari

31 Lẹ́yìn Ehudu, ni Ṣamgari ọmọ Anati ẹni ó pa ẹgbẹ̀ta (600) Filistini pẹ̀̀a fi ń da akọ màlúù, òun pẹ̀gba Israẹli kúrò nínú ìpọ́njú.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_12-11-46-