Pular para o conteúdo
Publicidade

Neemias 2

Nehemiah bẹ àwọn odi Jerusalẹmu

11 Mo lọ Jerusalẹmu, lẹ́yìn ìgbà mo dúró níbẹ̀ fún ọjọ́ mẹ́ta. 12 Mo jáde òru pẹ̀àwọn ọkùnrin díẹ̀. Èmi sọ fún ẹnìkankan ohun Ọlọ́run mi ti fi ọkàn mi láti ṣe fún Jerusalẹmu. ẹranko kankan pẹ̀mi, ṣe ̀kan ṣoṣo mo gùn.

13 òru, mo jáde lọ àfonífojì ibodè ìhà kànga Jakali àti ẹnu ibodè Ààtàn àti ẹnu ibodè rẹ̀ èyí ó ti odi Jerusalẹmu ó lulẹ̀, a ti fi iná sun. 14 Nígbà náà ni mo lọ ẹnu ibodè orísun àti adágún omi ọba, ṣùgbọ́n ààyè fún ẹranko mi láti kọjá; 15 bẹ́̀ ni mo gòkè àfonífojì òru, mo ń wo odi. ìparí, mo padà sẹ́yìn, mo tún wọlé láti ibodè àfonífojì. 16 Àwọn olórí mọ ibi mo lọ tàbí mọ ohun mo ń ṣe, nítorí èmi ì sọ fún àwọn ará Júù tàbí àwọn àlùfáà tàbí àwọn ọlọ́tàbí àwọn ìjòyè tàbí ẹnikẹ́ni mìíràn yóò máa ṣe iṣẹ́ náà.

Veja também