Pular para o conteúdo
Publicidade

Oséias 1

1 ̀rọ̀ Olúwa ó tọ Hosea ọmọ Beeri àkókò ìjọba Ussiah, Jotamu, Ahasi àti Hesekiah; àwọn ọba Juda àti àkókò ọba Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi Israẹli.

Ìdílé Hosea

2 Nígbà Olúwa bẹ̀rẹ̀ sọ̀rọ̀ láti ẹnu Hosea, Olúwa fún un , "Lọ, fẹ́ àgbèrè obìnrin kan fún ara rẹ, ó ọmọ àgbèrè fún nípasẹ̀ àwọn ọkùnrin mìíràn, nítorí ilẹ̀ ti ṣẹ ̀ṣẹ̀ àgbèrè púpọ̀ nípa yíyapa kúrò lọ́dọ̀ Olúwa." 3 Nígbà náà ni ó lọ, ó fẹ́ Gomeri ọmọbìnrin Diblaimu, ọmọbìnrin náà lóyún, ó ọmọkùnrin kan fún un.

4 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Hosea , "Pe orúkọ ọmọ náà Jesreeli, nítorí láìpẹ́ ni èmi yóò jẹ ìdílé Jehu ìyà fún ̀jẹ̀ àwọn ènìyàn pa ìpakúpa Jesreeli, Èmi yóò ìjọba Israẹli òpin. 5 ọjọ́ náà ni Èmi yóò ṣẹ́ ọrun Israẹli àfonífojì Jesreeli."

6 1.6,9: Ho 2.23; 1Pt 2.10. Gomeri tún lóyún, ó ọmọbìnrin kan. Olúwa sọ fún un , "Pe orúkọ rẹ̀ Lo-ruhama, nítorí , Èmi ṣàánú fún ilé Israẹli mọ́, Èmi dáríjì wọ́n. 7 Síbẹ̀, èmi yóò ṣàánú fún ilé Juda, èmi ó gbà wọ́ní ṣe nípa ọfà, idà tàbí ogun, ẹṣin tàbí kẹ̀kẹ́ ẹlẹ́ṣin ṣe nípa Olúwa Ọlọ́run wọn."

8 Lẹ́yìn ìgbà ó gba ọmú lẹ́nu Lo-ruhama, ó lóyún ó ọmọkùnrin mìíràn. Nígbà náà ni 9 Olúwa sọ fún un , "Pe orúkọ rẹ̀ Lo-Ammi, nítorí í ṣe ènìyàn mi, èmi náà í í ṣe Ọlọ́run yín.

10 "Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli yóò pọ̀ i iyanrìn etí Òkun a le wọ́n, a le è , yóò ṣe. ibi wọ́n ti sọ fún wọn . ̀yin í ṣe ènìyàn mi,níbẹ̀ ni a ó ti máa wọ́n Ọmọ Ọlọ́run alààyè.11 Àwọn ènìyàn Juda àti àwọn ènìyàn Israẹli yóò parapọ̀, wọn yóò yan olórí kan yóò jáde láti ilẹ̀ náà, nítorí ọjọ́ ńlá ni ọjọ́ Jesreeli yóò jẹ́.

Veja também