Pular para o conteúdo
Publicidade

Oséias 4

̀sùn Ọlọ́run fi kan Israẹli

1 gbọ́ ̀rọ̀ Olúwa ̀yin ọmọ Israẹli,

nítorí Olúwa fi ̀sùn

kan ̀yin ń gbé ilẹ̀ náà.

"ìwà òtítọ́, ìfẹ́,

ìmọ̀ Ọlọ́run ilẹ̀ náà,

2 àfi èpè, irọ́ pípa àti ìpànìyàn

olè jíjà àti panṣágà.

Wọ́n gbogbo òfin,

ìtàjẹ̀ sílẹ̀ ń gorí ìtàjẹ̀ sílẹ̀.

3 Nítorí èyí, ilẹ̀ náà ń ṣọ̀fọ̀,

gbogbo olùgbé ibẹ̀ ń ṣòfò dànù.

Ẹranko igbó àti ẹyẹ ojú ̀run

àti ẹja inú omi ń .

4 "Ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni ṣe ̀sùn ,

ẹnìkan ṣe fi ̀sùn kan ẹnìkejì

nítorí àwọn ènìyàn rẹ̀ dàbí

àwọn ti ń fi ̀sùn kan àlùfáà.

5 ń ṣubú lọ́sàn án àti lóru

àwọn wòlíì yín ń ṣubú pẹ̀yín.

Èmi ó pa ìyá rẹ run,

6 àwọn ènìyàn mi ń ṣègbé nítorí wọn ìmọ̀.

"Nítorí ti kọ ìmọ̀ sílẹ̀.

Èmi náà kọ̀ yín àlùfáà mi;

nítorí ti kọ òfin Ọlọ́run yín sílẹ̀,

Èmi náà yóò gbàgbé àwọn ọmọ yín.

7 àwọn àlùfáà ṣe ń pọ̀ i

bẹ́̀ ni wọ́n ṣe ń dẹ́ṣẹ̀ mi.

Wọ́n ògo mi padà ohun ìtìjú

8 wọ́n ń jẹun nípa ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn mi,

wọ́n ń gbádùn nínú ìwà búburú wọn.

9 Yóò ṣe gẹ́gẹ́ ènìyàn ṣe náà ni àwọn àlùfáà .

Èmi ó jẹ gbogbo wọn nítorí ̀wọn.

Èmi ó san án fún wọn gẹ́gẹ́ iṣẹ́ wọn.

10 "Wọn ó máa jẹun ṣùgbọ́n wọn ;

wọn ó ṣe àgbèrè ṣùgbọ́n, wọn ni pọ̀ i,

nítorí wọ́n ti kọ Olúwa sílẹ̀,

wọ́n ti fi ara wọn 11 fún àgbèrè;

wọ́n fi ara wọn fún wáìnì àtijọ́,

àti tuntun èyí gba òye àwọn ènìyàn mi sọnù.

12 Wọ́n ń gba ìmọ̀ràn lọ́wọ́ ère igi

̀igi ń wọn lóhùn.

̀àgbèrè ti wọn ṣìnà

wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ Ọlọ́run wọn.

13 Wọ́n ń ẹbọ lórí àwọn òkè ńlá,

wọ́n ń sun ọrẹ tùràrí lórí àwọn òkè kékeré,

lábẹ́ igi óákù, àti igi Poplari

àti igi ẹlimuati onírúurú igi ìbòjú rẹ̀ dára.

Nítorí náà àwọn ọmọbìnrin yín yóò ṣe àgbèrè

àti àwọn àfẹ́sọ́yín yóò ṣe àgbèrè.

14 "Èmi jẹ àwọn ọmọbìnrin yín

nígbà wọ́n ṣe àgbèrè

tàbí àwọn àfẹ́sọ́ọmọ yín,

nígbà wọ́n ṣe àgbèrè

nítorí àwọn ọkùnrin pàápàá ń alágbèrè kẹ́gbẹ́.

Wọ́n ń ẹbọ pẹ̀àwọn alágbèrè ojúbọ òrìṣà.

Nítorí náà, ènìyàn òye yóò parun!

15 "ó tilẹ̀ jẹ́ o ṣe àgbèrè ìwọ Israẹli,

ìdájọ́ yìí fún un yín. ṣe jẹ́ Juda di ẹlẹ́bi.

"ṣe lọ Gilgali.

ṣe gòkè lọ Beti-Afeni

búra , Olúwa ti láààyè nítòótọ́!’

16 Àwọn ọmọ Israẹli ṣe agídí

alágídí ọmọ màlúù.

Báwo ni Olúwa ṣe fẹ́ bọ́ wọn

àgùntàn pápá oko tútù?

17 Efraimu ti darapọ̀ mọ́

òrìṣà, fi sílẹ̀!

18 ohun mímu wọn tilẹ̀ tán,

wọ́n tún tẹ̀síwájú nínú àgbèrè.

Àwọn olórí wọn fẹ́ràn ohun ìtìjú ju ohun ìyìn lọ.

19 Ìjì ni yóò gbá wọn lọ.

Gbogbo ìrúbọ wọn yóò ìtìjú wọn.

Veja também