Publicidade

Provérbios 19

1 Ó sàn ènìyàn jẹ́ tálákà ìrìn rẹ̀ lábùkù

ju aláìgbọ́n ètè rẹ̀ jẹ́ àyídáyidà.

2 dára láti ìtara láìní ìmọ̀,

tàbí ènìyàn kánjú ó ṣìnà.

3 Ìwà òmùgọ̀ ènìyàn fúnra rẹ̀ a pa ̀rẹ̀ run;

síbẹ̀ ọkàn rẹ̀ yóò máa bínú Olúwa.

4 Ọrọ̀ máa ń fa ̀rẹ́ púpọ̀;

ṣùgbọ́n ̀rẹ́ tálákà tún kọ̀ ́ sílẹ̀.

5 Ajẹ́rìí èké lọ láìjìyà,

ẹni ó ń irọ́ jáde lọ lọ́fẹ̀́.

6 ̀pọ̀ ń ojúrere olórí;

gbogbo ènìyàn ni ̀rẹ́ ẹni ó lawọ́.

7 Gbogbo ará ilé e tálákà ni ó pa á ,

mélòó mélòó ni ti àwọn ̀rẹ́ rẹ̀ ń fún un!

ó tilẹ̀ ń wọn kiri pẹ̀̀bẹ̀,

tilẹ̀ le wọn rárá.

8 Ẹni ó gba ọgbọ́n fẹ́ràn ọkàn ara rẹ̀;

ẹni ó káràmáṣìkí òye yóò gbèrú.

9 Ajẹ́rìí èké yóò lọ láìjìyà

ẹni ó ń irọ́ jáde yóò parun.

10 yẹ aláìgbọ́n láti máa gbé nínú ọláńlá,

mélòó mélòó ó ti burú fún ẹrú láti jẹ ọba lórí ọmọ-aládé.

11 Ọgbọ́n ènìyàn a máa fún un sùúrù;

fún ògo rẹ̀ ni láti fojú fo àṣìṣe .

12 Ìbínú ọba dàbí kíké e kìnnìún,

ṣùgbọ́n ojúrere rẹ̀ dàbí ìrì lára koríko.

13 Aṣiwèrè ọmọ jẹ́ ìparun baba rẹ̀,

aya ó máa ń dàbí ̀ṣọ̀̀rọ̀ òjò.

14 A máa ń jogún ilé àti ọrọ̀ lọ́dọ̀ òbí,

ṣùgbọ́n aya olóye láti ̀dọ̀ Olúwa ni.

15 ̀lẹ ṣíṣe máa ń fa oorun sísùn fọnfọn,

ebi yóò máa pa ènìyàn ó lọ́ra.

16 Ẹnikẹ́ni ó gbọ́ ̀kọ́ pa ẹnu rẹ̀ mọ́,

ṣùgbọ́n ẹni ó kẹ́gàn ̀rẹ̀ yóò .

17 Ẹni ó ṣàánú tálákà, Olúwa ó ,

yóò pín in lérè ohun ó ti ṣe.

18 ọmọ rẹ nítorí nínú ìyẹn ni ìrètí ;

àìṣe bẹ́̀ ìwọ lọ́wọ́ nínú ìparun un rẹ̀.

19 Ènìyàn onínú-fùfù gbọdọ̀ gba èrè ìwà rẹ̀;

ìwọ gbà á , ìwọ yóò tún láti ṣe é lẹ́̀kan i.

20 Fetí ìmọ̀ràn o gba ̀kọ́,

ìgbẹ̀yìn gbẹ́yín ìwọ yóò di ọlọ́gbọ́n.

21 ̀pọ̀lọpọ̀ ni ète inú ọkàn ènìyàn,

ṣùgbọ́n ìfẹ́ Olúwa ó máa ń borí.

22 Ohun ènìyàn ń fẹ́ ni ìfẹ́ í yẹ̀;

ó sàn láti jẹ́ tálákà ju òpùrọ́ lọ.

23 Ìbẹ̀Olúwa ń ìyè ;

nígbà náà ọkàn ń balẹ̀, láìsí ewu.

24 ̀lẹ ki ọwọ́ rẹ̀ bọ inú àwo oúnjẹ;

tilẹ̀ u padà ẹnu rẹ̀.

25 Na ẹlẹ́gàn, òpè yóò kọ́gbọ́n;

olóye ènìyàn , yóò ìmọ̀ i.

26 Ẹni ó ṣìkà baba rẹ̀, ó ìyá rẹ̀ jáde

òun ni ọmọ ń ṣe ìtìjú, ó ̀gàn .

27 Ọmọ mi, dẹ́kun láti tẹ́̀kọ́,

í ni ṣìnà kúrò nínú ̀rọ̀-ìmọ̀.

28 Ẹlẹ́rìí búburú fi ìdájọ́ ṣẹ̀sín,

ẹnu ènìyàn búburú ń gbé ibi .

29 A ti pèsè ìjìyà sílẹ̀ fún ẹlẹ́gàn;

àti pàṣán fún ̀yìn àwọn aṣiwèrè.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-