Publicidade

Provérbios 21

1 Ọkàn ọba ń bẹ lọ́wọ́ Olúwa;

a máa darí rẹ̀ lọ ibi ó fẹ́ ipa omi.

2 Gbogbo ̀ènìyàn dàbí i ó dára lójú rẹ̀,

ṣùgbọ́n, Olúwa ń díwọ̀n ọkàn.

3 Ṣíṣe ohun ó dára ó tọ̀

ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà Olúwa ju ẹbọ lọ.

4 Ojú ó gbéga àti ọkàn ìgbéraga,

ìmọ́lẹ̀ àwọn ènìyàn búburú, ̀ṣẹ̀ ni!

5 Ètè àwọn olóye jásí èrè

ìkánjú ṣe máa ń fa òsì kíákíá.

6 Ìṣúra a kójọ nípasẹ̀ ahọ́n ń parọ́

jẹ́ ìrì lásán àti ìkẹ́kùn ikú.

7 Ìwà ipá àwọn ènìyàn búburú yóò wọ́ wọn lọ,

nítorí wọ́n kọ̀ láti ṣe ohun ó tọ́.

8 ̀ẹlẹ́ṣẹ̀ kún fún ìwà ̀ṣẹ̀

ṣùgbọ́n iṣẹ́ onínú funfun jẹ́ títọ́.

9 Ó sàn láti máa gbé kọ̀rọ̀ orí òrùlé

ju láti ṣe àjọpín ilé pẹ̀aya oníjà.

10 Ènìyàn búburú ń fẹ́ ibi

aládùúgbò rẹ̀ í àánú kankan gbà lọ́dọ̀ rẹ̀.

11 Nígbà a ń fìyà jẹ ẹlẹ́gàn,

òpè a máa kọ́gbọ́n,

nígbà a kọ́ ọlọ́gbọ́n yóò ìmọ̀.

12 Olódodo ṣàkíyèsí ilé ènìyàn búburú

ó ènìyàn búburú ìparun.

Ìṣúra ẹni o gbọ́n

13 Ẹnikẹ́ni ó ti di etí rẹ̀ igbe olùpọ́njú,

òun tìkára rẹ̀ yóò pẹ̀;

ṣùgbọ́n a yóò gbọ́.

14 ̀rẹ́ ìkọ̀kọ̀, ìbínú kúrò:

àti owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ láti ibi ìkọ̀kọ̀ ,

dẹ́kun ìbínú líle.

15 Ayọ̀ ni fún olódodo láti ṣe ìdájọ́:

ṣùgbọ́n ìparun ni fún àwọn oníṣẹ́ ̀ṣẹ̀.

16 Ẹni ó kúrò ̀òye,

yóò máa gbé inú ìjọ àwọn òkú.

17 Ẹni ó fẹ́ afẹ́, yóò di tálákà:

ẹni ó fẹ́ ọtí wáìnì pẹ̀òróró le lọ́rọ̀.

18 Ènìyàn búburú ni yóò ṣe owó ìràpadà fún olódodo,

àti olùrékọjá fún ẹni dídúró ṣinṣin.

19 Ó sàn láti jókòó aginjù ju pẹ̀

oníjà obìnrin àti òṣónú lọ.

20 Ìṣúra iyebíye àti òróró ibùgbé ọlọ́gbọ́n;

ṣùgbọ́n òmùgọ̀ ènìyàn n á jẹ́.

21 Ẹni ó tẹ̀òdodo àti àánú yóò ìyè,

òdodo, àti ọlá.

22 Ọlọ́gbọ́n gòkè odi ìlú àwọn alágbára,

ó bi ibi gíga agbára ìgbẹ́kẹ̀wọn ṣubú.

23 Ẹnikẹ́ni ó pa ẹnu àti ahọ́n rẹ̀ mọ́,

ó pa ọkàn rẹ̀ mọ́ kúrò nínú ìyọnu.

24 Agbéraga àti alágídí ènìyàn ń gan orúkọ ara rẹ̀ nítorí ó ń hùwà nínú ìwà ìgbéraga rẹ̀,

àti nínú ìbínú púpọ̀púpọ̀.

25 Ẹlẹ́rìí èké yóò ṣègbé, àwọn ó gbọ́ ̀rọ̀ rẹ̀ yóò parun láé;

nítorí ọwọ́ rẹ̀ kọ iṣẹ́ ṣíṣe.

26 Ó ń fi ìlara ṣe ojúkòkòrò gbogbo ọjọ́:

ṣùgbọ́n olódodo a máa fi fún ni í í dáwọ́ dúró.

27 Ẹbọ ènìyàn búburú, ìríra ni:

mélòó mélòó ni nígbà ó un pẹ̀èrò ìwà ibi?

28 Ẹlẹ́rìí èké yóò ṣègbé:

ṣùgbọ́n ̀rọ̀ ẹni ó gbọ́, yóò dúró.

29 Ènìyàn búburú ojú ara rẹ̀ le:

ṣùgbọ́n ẹni ìdúró ṣinṣin ni ó ń ̀rẹ̀ tọ́.

30 ọgbọ́n, ìmòye,

tàbí ìmọ̀ràn ó le mókè níwájú Olúwa.

31 A ń múra ẹṣin sílẹ̀ de ọjọ́ ogun:

ṣùgbọ́n ìṣẹ́gun jẹ́ ti Olúwa.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-29_22-07-56-