Publicidade

Provérbios 27

1 ṣe yangàn nítorí ̀la

nítorí o mọ ohun ọjọ́ kan le è wáyé.

2 Jẹ́ ẹlòmíràn yìn ́ dípò ẹnu ara rẹ,

àní àlejò, ó ṣe ètè ìwọ fúnra rẹ̀.

3 Òkúta wúwo, erùpẹ̀ wúwo

ṣùgbọ́n ìbínú aṣiwèrè wúwo ju méjèèjì lọ.

4 Ìbínú ni ìkà, ìrunú burú púpọ̀

ṣùgbọ́n ta ni ó le è dúró níwájú owú?

5 Ìbániwí gbangba sàn

ju ìfẹ́ ìkọ̀kọ̀ lọ.

6 Òtítọ́ ni ọgbẹ́ ̀rẹ́,

ṣùgbọ́n ìfẹnukonu ̀ni ̀tàn.

7 Kódà oyin dùn lẹ́nu ẹni ó ti

ṣùgbọ́n òróǹró gan an dùn lẹ́nu ẹni ebi ń pa.

8 ẹyẹ ó ṣáko lọ kúrò níbi ìtẹ́ rẹ̀

ni ènìyàn ó ṣáko lọ kúrò ilé rẹ̀.

9 Ìpara olóòórùn dídùn àti tùràrí ń ayọ̀ sínú ọkàn

bẹ́̀ ni inú dídùn láti ̀dọ̀ ̀rẹ́ ń láti inú ìmọ̀ràn ó ṣàkóso.

10 ṣe kọ ̀rẹ́ rẹ àti ̀rẹ́ baba rẹ sílẹ̀,

ṣe lọ sílé arákùnrin rẹ nígbà ìdààmú

ó sàn o jẹ́ aládùúgbò ó súnmọ́ ni ju arákùnrin ó jìnnà ni.

11 Gbọ́n, ọmọ mi, o ayọ̀ sínú ọkàn mi

nígbà náà ni mo le gbogbo ẹni ó kẹ́gàn mi.

12 Ọlọ́gbọ́n ewu, ó fi ara pamọ́

ṣùgbọ́n aláìgbọ́n , kàkà ó dúró ó tẹ̀síwájú, ó jìyà rẹ̀.

13 Gba aṣọ ẹni ó ṣe onídùúró fún àjèjì

fi ṣe ̀ìdúró o ṣe onídùúró fún obìnrin oníṣekúṣe.

14 ènìyàn kan ń kígbe súre fún aládùúgbò rẹ òwúrọ̀

a ó á èpè.

15 Àyà ó máa ń dàbí

̀wààrà òjò ọjọ́ òjò ń rọ̀;

16 dídá a lẹ́kun dàbí ìgbà ènìyàn ń afẹ́fẹ́ lẹ́kun

tàbí ẹni ó gbá òróró.

17 irin ń pọ́n irin

bẹ́̀ ni ènìyàn kan ń pọ́n ẹlòmíràn .

18 Ẹni ó tọ́igi ̀pọ̀tọ́ yóò jẹ èso rẹ̀

ẹni ó fojú ̀rẹ̀ yóò gba ọlá.

19 omi ń ṣe àfihàn ojú, nígbà a ó

bẹ́̀ ni ọkàn ènìyàn ń ṣe àfihàn ènìyàn.

20 tẹ́ ikú àti ìparun lọ́rùn

bẹ́̀ pẹ̀ni ojú ènìyàn ìtẹ́lọ́rùn .

21 Iná fún fàdákà iná ìléru fún wúrà,

ṣùgbọ́n a ń dán ènìyàn nípa ìyìn ó ń gbà.

22 a tilẹ̀ gún aláìgbọ́n nínú odó,

fi ọmọ odó gún un èlùbọ́

ìwọ yóò le è yọ ìwà òmùgọ̀ rẹ̀ kúrò inú rẹ̀.

23 i dájú o mọ ipò àwọn agbo àgùntàn rẹ

bojútó àwọn agbo màlúù rẹ dáradára;

24 nítorí ọrọ̀ í pẹ́ lọ títí

adé í í lórí títí láéláé.

25 Nígbà a koríko, ewéko tuntun yóò jáde, a ó koríko àwọn orí òkè wọlé

26 àwọn àgùntàn yóò pèsè aṣọ fún ,

àti ewúrẹ́ yóò pèsè owó oko.

27 Ìwọ yóò ̀pọ̀lọpọ̀ wàrà ewúrẹ́

láti bọ́ àti ìdílé rẹ

àti láti tọ́àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-