Publicidade

Provérbios 3

Àwọn àǹfààní ọgbọ́n mìíràn

1 Ọmọ mi, ṣe gbàgbé ̀kọ́ mi.

Ṣùgbọ́n pa òfin mi mọ́ ọkàn rẹ.

2 Nítorí ọjọ́ gígùn, ̀gígùn, àti àlàáfíà,

ni wọn yóò fi kùn un fún .

3 ṣe jẹ́ ìfẹ́ àti òtítọ́ ṣíṣe fi ́ sílẹ̀ láéláé

so wọ́n mọ́ ọrùn rẹ,

kọ wọ́n wàláà àyà rẹ.

4 Nígbà náà ni ìwọ yóò ojúrere àti orúkọ rere

ojú Ọlọ́run àti lójú ènìyàn.

5 Gbẹ́kẹ̀Olúwa pẹ̀gbogbo ọkàn rẹ

ṣe sinmi òye ara à rẹ.

6 Mọ̀ ́n gbogbo ̀rẹ

òun yóò máa tọ́ ipa ̀rẹ.

7 ṣe jẹ́ ọlọ́gbọ́n lójú ara à rẹ

bẹ̀Olúwa o kórìíra ibi.

8 Èyí yóò ìlera fún ara rẹ

àti okun fún àwọn egungun rẹ.

9 Fi ọrọ̀ rẹ bọ̀wọ̀ fún Olúwa,

pẹ̀àkọ́so oko rẹ,

10 nígbà náà ni àká rẹ yóò kún àkúnya

àgbá rẹ yóò kún àkúnwọ́sílẹ̀ fún wáìnì tuntun.

11 Ọmọ mi, ṣe kẹ́gàn ìbáwí Olúwa

ṣe bínú nígbà ó ń ,

12 nítorí Olúwa a máa àwọn ó fẹ́ràn

baba ti í ọmọ ó nínú dídùn .

13 Ìbùkún ni fún ẹni ó ìmọ̀,

ẹni ó tún òye i,

14 nítorí ó ṣe èrè ju fàdákà lọ

ó èrè lórí ju wúrà lọ.

15 Ó ṣe iyebíye ju iyùn lọ;

ohunkóhun a fiwé e nínú ohun gbogbo ìwọ fẹ́.

16 ̀gígùn ń bẹ ọwọ́ ̀tún rẹ̀;

ọwọ́ òsì rẹ ni ọrọ̀ àti ọlá.

17 Àwọn ̀rẹ jẹ́ ̀ìtura,

òpópónà rẹ jẹ́ ti àlàáfíà.

18 Igi ìyè ni ó jẹ́ fún gbogbo ẹni ó gbà á;

àwọn ó dìímú yóò ìbùkún gbà.

19 Nípa ọgbọ́n, Olúwa fi ìpìlẹ̀ ilẹ̀ ayé sọlẹ̀; nípa òye, ó fi àwọn ̀run ipò wọn;

20 nípa ìmọ̀ rẹ̀ ó pín ibú omi ,

àwọsánmọ̀ ń sẹ ìrì.

21 Ọmọ mi, pa ọgbọ́n ó kooro àti ìmòye mọ́,

jẹ́ wọn lọ kúrò ibi ojú rẹ ti le wọn.

22 Wọn yóò jẹ́ ìyè fún ,

àti ̀ṣọ́ fún ọrùn rẹ.

23 Nígbà náà ni ìwọ yóò ̀rẹ lọ àìléwu,

ìwọ yóò kọsẹ̀.

24 Nígbà ìwọ dùbúlẹ̀, ìwọ yóò bẹ̀,

nígbà ìwọ dùbúlẹ̀, oorun rẹ yóò jẹ́ oorun ayọ̀.

25 ṣe bẹ̀ìdààmú òjijì,

tàbí ti ìparun ó ń àwọn ènìyàn búburú.

26 Nítorí Olúwa yóò jẹ́ ìgbẹ́kẹ̀rẹ,

yóò jẹ́ ẹsẹ̀ rẹ bọ́ sínú pàkúté.

27 ṣe fa ọwọ́ ìre sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ àwọn ṣe tìrẹ,

nígbà ó ìkápá rẹ láti ṣe ohun kan.

28 ṣe fún aládùúgbò rẹ ,

"Padà nígbà ṣe díẹ̀; èmi yóò fi fún ̀la,"

nígbà o i pẹ̀rẹ nísinsin yìí.

29 ṣe pète ohun búburú fún aládùúgbò rẹ,

ti o gbé nítòsí rẹ, ó fọkàn tán .

30 ṣe fẹ̀sùn kan ènìyàn láìnídìí,

nígbà ṣe ́ ibi kankan rárá.

31 ṣe ṣe ìlara ènìyàn jàgídíjàgan

tàbí o yàn láti rìn ̀rẹ̀.

32 Nítorí Olúwa kórìíra ènìyàn aláyídáyidà

ṣùgbọ́n a máa fọkàn tán ẹni dídúró ṣinṣin.

33 Ègún Olúwa ń bẹ lórí ilé ènìyàn búburú,

ṣùgbọ́n ó bùkún fún ilé olódodo.

34 Ó fi àwọn ẹlẹ́ṣe yẹ̀yẹ́,

ṣùgbọ́n ó fi oore-ọ̀fẹ́ fún onírẹ̀lẹ̀.

35 Ọlọ́gbọ́n jogún iyì,

ṣùgbọ́n àwọn aṣiwèrè ni yóò ru ìtìjú wọn.

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-