Publicidade

Provérbios 31

10 Ta ni ó le aya oníwà rere?

Ó níye lórí ju iyùn lọ.

11 Ọkọ rẹ̀ ìgbẹ́kẹ̀púpọ̀ nínú rẹ̀

ṣí ìwà rere lọ́wọ́ rẹ̀.

12 Ire ó ń ṣe fún un, í ṣe ibi

gbogbo ọjọ́ ayé rẹ̀.

13 Ó sa aṣọ irun àgùntàn olówùú àti ̀gbọ̀

Ó ṣiṣẹ́ pẹ̀ìyárí.

14 Ó dàbí ọkọ̀ ojú omi àwọn oníṣòwò;

ó ń gbé oúnjẹ rẹ̀ láti ̀jíjìn.

15 Ó dìde nígbà òkùnkùn kùn;

ó ṣe oúnjẹ fún ìdílé rẹ̀

àti ìpín oúnjẹ fún àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀.

16 Ó kíyèsi oko kan, ó á;

nínú ohun ó ń wọlé fún un ó gbin ọgbà àjàrà rẹ̀.

17 Ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ tagbára tagbára

apá rẹ̀ le koko fún iṣẹ́.

18 Ó i òwò òun

fìtílà rẹ̀ í í òru.

19 ọwọ́ rẹ̀, ó di kẹ̀kẹ́ òwú

ó na ọwọ́ rẹ̀ di ìrànwú .

20 O la ọwọ́ rẹ̀ àwọn tálákà

ó na ọwọ́ rẹ̀ àwọn aláìní.

Veja também

Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-07-05_19-25-13-