Pular para o conteúdo
Publicidade

Òwe 6

Ìkìlọ̀ nítorí àgbèrè

20 Ọmọ mi, pa àṣẹ baba rẹ mọ́

ṣe kọ ̀kọ́ ìyá rẹ sílẹ̀.

21 Jẹ́ wọn nínú ọkàn rẹ láéláé

so wọ́n mọ́ ọrùn rẹ.

22 Nígbà ìwọ ń rìn, wọn yóò ṣe amọ̀rẹ;

nígbà ìwọ sùn, wọn yóò máa ṣe olùṣọ́ rẹ;

nígbà o , wọn yóò sọ̀rọ̀.

23 Nítorí àwọn àṣẹ yìí jẹ́ fìtílà,

̀kọ́ yìí jẹ́ ìmọ́lẹ̀,

àti ìtọ́nisọ́ti ìbáwí

ni ̀ìyè.

Estes versículos te tocaram? Ore agora!

+581 estão orando agora.

Junte-se à corrente de oração.

Veja também