Publicidade

Graça

Por Bíblia Online

A graça de Deus é favor imerecido. Pela graça somos salvos, pela graça vivemos, pela graça somos sustentados. É o dom mais precioso de Deus — dado a quem não merece.

Salvos pela graça

Pela graça sois salvos, mediante a fé, e isto não vem de vós — é dom de Deus. Não por obras, para que ninguém se glorie.

Nítorí oore-ọ̀fẹ́ a fi gbà yín nípa ìgbàgbọ́. Èyí í ṣe nípa agbára ̀yin fúnra yín: ̀bùn Ọlọ́run ni, í ṣe nípa àwọn iṣẹ́, ẹnikẹ́ni ba à ṣògo.

Ṣùgbọ́n Ọlọ́run, ẹni í ṣe ọlọ́rọ̀ ni àánú, nítorí ìfẹ́ ńlá rẹ̀ ó fi fẹ́ wa, nígbà àwa tilẹ̀ ti nítorí ìrékọjá wa, ó sọ di ààyè pẹ̀Kristi, oore-ọ̀fẹ́ ni a ti fi gbà yín .

Gbogbo ènìyàn ni ó ṣá ti ṣẹ̀, wọ́n kùnà ògo Ọlọ́run, àwọn ẹni a ń láre lọ́fẹ̀́ nípa oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀, nípa ìdáǹdè ó nínú Kristi Jesu.

Ṣùgbọ́n ̀bùn ̀fẹ́ dàbí ̀ṣẹ̀. Nítorí nípa ̀ṣẹ̀. Nítorí o jẹ ẹnìkan ẹni púpọ̀ , mélòó mélòó ni oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run, àti ̀bùn nínú oore-ọ̀fẹ́ ọkùnrin kan, Jesu Kristi, di púpọ̀ fún ẹni púpọ̀.

, gẹ́gẹ́ ̀ṣẹ̀ ti jẹ ọba nípa ikú bẹ́̀ ni oore-ọ̀fẹ́ jẹ ọba nípa òdodo títí ìyè àìnípẹ̀kun nípasẹ̀ Jesu Kristi Olúwa wa.

Graça que capacita

A graça me basta, pois o poder se aperfeiçoa na fraqueza. Na graça, não estamos mais sob a lei, mas sob o favor de Deus.

Nítorí ̀ṣẹ̀ yóò tún ipá lórí yín mọ́, nítorí ̀yin lábẹ́ ìdè òfin, ṣe lábẹ́ oore-ọ̀fẹ́.

Ẹrú ìṣòdodo

Ǹjẹ́ èyí túmọ̀ , nísinsin yìí, a tẹ̀síwájú láti máa dẹ́ṣẹ̀ láìbìkítà, nítorí ìgbàlà wa dúró nípa òfin mọ́, ṣe nípa gbígba oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run!

ẹni ti ó gbà , ti ó si sínú ìwà mímọ́—í ṣe nípa iṣẹ́ a ṣe ṣùgbọ́n nípasẹ̀ ète àti oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀. Oore-ọ̀fẹ́ yìí ni a fi fún wa nínú Kristi Jesu láti ìpìlẹ̀ ayérayé,

Nítorí oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run ìgbàlà ti fi ara hàn fún gbogbo ènìyàn. Ó ń kọ́ wa láti sẹ́ àìwà-bí-Ọlọ́run àti ìfẹ́kúfẹ̀́ ayé, a máa àìrékọjá, òdodo àti ìwà-bí-Ọlọ́run ayé ìsinsin yìí,

jẹ́ mímọ́

Nítorí náà, múra ọkàn yín sílẹ̀, ara yín ìjánu, fi ìrètí yín kíkún oore-ọ̀fẹ́, èyí a ń mu bọ̀ fún yin ni ìgbà ìfarahàn Jesu Kristi.

Ọlọ́run oore-ọ̀fẹ́ gbogbo, ó ti yín sínú ògo rẹ̀ nípẹ̀kun nínú Kristi Jesu, nígbà ̀yin ti jìyà díẹ̀, òun tìkára rẹ̀, yóò ṣe yín àṣepé, yóò fi ẹsẹ̀ yín múlẹ̀, yóò fún yín lágbára, yóò fi ìdí yín kalẹ̀.

A graça de Deus

O Senhor é compassivo e gracioso, tardio em irar-se e grande em amor. Sua graça é nova a cada manhã.

Olúwa ni aláàánú àti olóore,

ó lọ́ra láti bínú, ó pọ̀ ìfẹ́.

Nítòótọ́, ìre àti àánú ni yóò máa tọ̀ lẹ́yìn

ọjọ́ ayé è mi gbogbo,

èmi yóò máa gbé inú ilé Olúwa

títí láéláé.

Jẹ́ ẹwà Olúwa Ọlọ́run wa lára wa;

fi ìdí iṣẹ́ ọwọ́ wa múlẹ̀ lára wa,

bẹ́̀ ni, ó fi ìdí iṣẹ́ ọwọ́ wa múlẹ̀.

Orin fún ìgòkè.

Láti inú ibú ni

èmi ń é ́ Olúwa

Olúwa, gbóhùn mi,

jẹ́ etí rẹ o tẹ́ sílẹ̀ ohùn ̀bẹ̀ mi.

" ‘ "Olúwa bùkún un yín,

ó pa yín mọ́.

Olúwa o ojú rẹ̀ ó mọ́lẹ̀ i yín lára.

ó ṣàánú fún un yín.

Olúwa bojú yín,

ó fún un yín àlàáfíà." 

Síbẹ̀síbẹ̀ Olúwa fẹ́ síjú àánú ́;

ó dìde láti ṣàánú fún .

Nítorí Olúwa jẹ́ Ọlọ́run ìdájọ́.

Ìbùkún ni fún gbogbo àwọn ó dúró é!

Viver pela graça

A graça de nosso Senhor Jesus Cristo esteja convosco. Perdoando e confessando, experimentamos a graça restauradora.

Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Olúwa ó pẹ̀gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́. Àmín.

oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa pẹ̀̀yín.

Nítorí náà, jẹ́ a si ibi ìtẹ́ oore-ọ̀fẹ́ pẹ̀ìgboyà, a àánú gbà, a oore-ọ̀fẹ́ láti máa ran ni lọ́wọ́ àkókò ó wọ̀.

Ṣùgbọ́n èmi ka ọkàn mi nǹkan rárá bi ohun ó ṣọ̀wọ́n fún mi àti iṣẹ́ ìránṣẹ́ mo gbà lọ́dọ̀ Jesu Olúwa, láti máa ròyìn ìyìnrere oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run.

"Nítorí Ọlọ́run fẹ́ aráyé bẹ́̀ gẹ́́, ó fi ọmọ rẹ̀ kan ṣoṣo fún ni, ẹnikẹ́ni ó gbà á gbọ́, á ṣègbé, ṣùgbọ́n ó ìyè àìnípẹ̀kun.

Nítorí náà, ̀yin dárí àwọn ṣẹ̀ yín, baba yín ̀run náà yóò dáríjì yín.

Ẹni ó bo ̀ṣẹ̀ rẹ̀ mọ́lẹ̀ yóò ṣe rere,

ṣùgbọ́n ẹni ó jẹ́wọ́ ó kọ̀ wọ́n sílẹ̀ máa ń àánú gbà.

Hesekiah ṣe àsè ìrékọjá

Hesekiah ránṣẹ́ gbogbo Israẹli àti Juda, ó kọ ìwé Efraimu àti Manase, wọn ó sínú ilé Olúwa Jerusalẹmu láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ Olúwa Ọlọ́run Israẹli. Nítorí ọba ti gbìmọ̀ àti àwọn ìjòyè rẹ̀, àti gbogbo ìjọ ènìyàn Jerusalẹmu, láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ oṣù kejì. Nítorí wọn pa á mọ́ àkókò náà, nítorí àwọn àlùfáà i ya ara wọn mímọ́ ; bẹ́̀ ni àwọn ènìyàn ì ara wọn jọ Jerusalẹmu. ̀rọ̀ náà tọ́ lójú ọba àti lójú gbogbo ìjọ ènìyàn. Bẹ́̀ ni wọ́n fi àṣẹ kan lélẹ̀, láti kéde gbogbo Israẹli láti Beerṣeba àní títí Dani, láti pa àjọ ìrékọjá mọ́ Olúwa Ọlọ́run Israẹli Jerusalẹmu: nítorí wọn pa á mọ́ ọjọ́ púpọ̀ gẹ́gẹ́ a ti kọ ́.

Bẹ́̀ àwọn oníṣẹ́ ń sáré lọ pẹ̀ìwé láti ọwọ́ ọba àti àwọn ìjòyè rẹ̀ gbogbo Israẹli àti Juda; àti gẹ́gẹ́ àṣẹ ọba, ,

"̀yin ọmọ Israẹli padà Olúwa Ọlọ́run Abrahamu, Isaaki, àti Israẹli, òun ó yípadà àwọn ìyókù nínú yín, ó sálà kúrò lọ́wọ́ àwọn ọba Asiria. ̀yin ó ṣe dàbí àwọn baba yín, àti àwọn arákùnrin yín ó dẹ́ṣẹ̀ Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn, nítorí náà ó ṣe fi wọ́n fún ìdahoro ̀yin ti . Ǹjẹ́ ̀yin ó ṣe ṣe ọlọ́rùn líle, àwọn baba yín, ṣùgbọ́n jọ̀wọ́ ara yín lọ́wọ́ fún Olúwa, wọ inú ibi mímọ́ rẹ̀ lọ, ti òun ti ìyàsímímọ́ títí láé. sin Olúwa, Ọlọ́run yín gbígbóná ìbínú rẹ̀ ó yípadà kúrò ̀dọ̀ yín. Nítorí ̀yin tún yípadà Olúwa, àwọn arákùnrin yín, àti àwọn ọmọ yín, yóò àánú níwájú àwọn ó wọn ìgbèkùn lọ, wọn ó tún padà ilẹ̀ : nítorí Olúwa Ọlọ́run yín, oníyọnu àti aláàánú ni, yóò ojú rẹ̀ padà kúrò lọ́dọ̀ yín, ̀yin padà sọ́dọ̀ rẹ̀."

Bẹ́̀ ni àwọn oníṣẹ́ náà kọjá láti ìlú ìlú, ilẹ̀ Efraimu àti Manase títí Sebuluni, ṣùgbọ́n wọ́n fi wọ́n rẹ́rìn-ín ẹlẹ́, wọ́n gàn wọ́n. Síbẹ̀ òmíràn nínú àwọn ènìyàn Aṣeri àti Manase àti Sebuluni rẹ̀ ara wọn sílẹ̀, wọ́n Jerusalẹmu. Juda pẹ̀, ọwọ́ Ọlọ́run láti fún wọn ọkàn kan láti pa òfin ọba mọ́ àti àwọn ìjòyè, nípa ̀rọ̀ Olúwa.

̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn péjọ Jerusalẹmu, láti pa àjọ àkàrà àìwú mọ́ oṣù kejì. Wọ́n dìde, wọ́n gbogbo pẹpẹ ó Jerusalẹmu lọ, àti gbogbo pẹpẹ tùràrí ni wọ́n lọ, wọ́n wọ́n odò Kidironi.

Nígbà náà ni wọ́n pa ẹran ìrékọjá náà ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kejì: ojú ti àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, wọ́n ara wọn mímọ́, wọ́n ẹbọ sísun sínú ilé Olúwa. Wọ́n dúró ipò wọn, ètò wọn gẹ́gẹ́ òfin Mose, ènìyàn Ọlọ́run: àwọn àlùfáà wọ́n ̀jẹ̀ náà, wọ́n gbà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Lefi. Nítorí ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó nínú ìjọ ènìyàn náà ara wọn mímọ́: nítorí náà ni àwọn ọmọ Lefi ṣe ń tọ́àti pa ẹran ìrékọjá fún olúkúlùkù ẹni ó ṣe aláìmọ́, láti á mímọ́ Olúwa. ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àní ̀pọ̀lọpọ̀ nínú Efraimu àti Manase, Isakari, àti Sebuluni wẹ̀ ara wọn mọ́ síbẹ̀ wọ́n jẹ ìrékọjá náà, í ṣe gẹ́gẹ́ a ti kọ ́. Ṣùgbọ́n Hesekiah bẹ̀bẹ̀ fún wọn, , Olúwa, ẹni rere, dáríjì olúkúlùkù, ó múra ọkàn rẹ̀ láti Ọlọ́run, Olúwa Ọlọ́run àwọn baba rẹ̀ ṣùgbọ́n í ṣe nípa ìwẹ̀nùmọ́ mímọ́ Olúwa gbọ́ ti Hesekiah, ó àwọn ènìyàn náà láradá.

Àwọn ọmọ Israẹli a Jerusalẹmu fi ayọ̀ ńlá pa àjọ àkàrà àìwú mọ́ ọjọ́ méje: àwọn ọmọ Lefi, àti àwọn àlùfáà yin Olúwa lójoojúmọ́, wọ́n ń fi ohun èlò olóhùn gooro kọrin Olúwa.

Hesekiah sọ̀rọ̀ ìtùnú fún gbogbo àwọn ọmọ Lefi, ó lóye ìmọ̀ rere Olúwa: ọjọ́ méje ni wọ́n fi jẹ àsè náà wọ́n ẹbọ àlàáfíà, wọ́n ń fi ohùn rara dúpẹ́ fún Olúwa, Ọlọ́run àwọn baba wọn.

Gbogbo ìjọ náà gbìmọ̀ láti pa ọjọ́ méje mìíràn mọ́: wọ́n fi ayọ̀ pa ọjọ́ méje mìíràn mọ́. Nítorí Hesekiah, ọba Juda, ta ìjọ ènìyàn náà ọrẹ, ẹgbẹ̀rún (1,000) akọ màlúù, àti ̀́dẹ́gbàárin (7,000) àgùntàn. ̀pọ̀lọpọ̀ nínú àwọn àlùfáà ya ara wọn mímọ́. Gbogbo ìjọ ènìyàn Juda pẹ̀àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, àti gbogbo ìjọ ènìyàn ó ti inú Israẹli jáde , àti àwọn àjèjì ó ti ilẹ̀ Israẹli jáde , àti àwọn ń gbé Juda yọ̀. Bẹ́̀ ni ayọ̀ ńlá Jerusalẹmu: nítorí láti ọjọ́ Solomoni, ọmọ Dafidi, ọba Israẹli, irú èyí Jerusalẹmu. Nígbà náà ni àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi dìde, wọ́n súre fún àwọn ènìyàn náà: a gbọ́ ohùn wọn, àdúrà wọn gòkè lọ si ibùgbé mímọ́ rẹ̀, àní ̀run.

Seja o primeiro
Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-