Publicidade

Deuteronômio 33

Mose bùkún fún àwọn ̀

1 Èyí ni ìbùkún Mose ènìyàn Ọlọ́run bùkún fún àwọn ọmọ Israẹli ó . 2 Ó ,

"Olúwa ti Sinai ,

ó yọ wọn láti Seiri

ó tàn án jáde láti òkè Parani .

Ó ti ̀dọ̀ ẹgbẹgbàarùn-ún àwọn mímọ́

láti ọwọ́ ̀tún rẹ̀ ni òfin kan a iná ti jáde fún wọn .

3 Nítòótọ́, ó fẹ́ràn àwọn ènìyàn an rẹ̀,

gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́ ọwọ́ rẹ̀.

ẹsẹ̀ rẹ̀ ni wọ́n ti foríbalẹ̀,

àti lọ́dọ̀ rẹ̀ ni wọ́n ti ń gba ̀rọ̀,

4 òfin Mose fi fún wa,

ìní ti ìjọ ènìyàn Jakọbu.

5 Òun ni ọba lórí Jeṣuruni

ìgbà olórí àwọn ènìyàn péjọpọ̀,

pẹ̀àwọn ̀Israẹli.

6 "Jẹ́ Reubeni ó ṣe ,

tàbí ènìyàn rẹ mọ níwọ̀n."

7 Èyí ni ohun ó sọ nípa Juda:

"Olúwa gbọ́ ohùn Juda

o tọ àwọn ènìyàn rẹ̀ .

ọwọ́ rẹ̀ ó fún un,

ó ṣe ìrànlọ́wọ́ fún lọ́wọ́ àwọn ̀rẹ̀!"

8 ti Lefi ó ,

"Jẹ́ Tumimu àti Urimu rẹ ó

pẹ̀ẹni mímọ́ rẹ.

Ẹni ó dánwò Massa,

ìwọ omi Meriba.

9 Ó fún baba àti ìyá rẹ ,

Èmi buyì fún wọn.

mọ àwọn arákùnrin rẹ̀,

tàbí mọ àwọn ọmọ rẹ̀,

ṣùgbọ́n ó dúró lórí ̀rọ̀ rẹ̀,

ó pa májẹ̀rẹ̀ mọ́.

10 Ó kọ́ Jakọbu ìdájọ́ rẹ̀

àti Israẹli òfin rẹ̀.

Ó tùràrí síwájú rẹ̀

àti ̀tọ̀̀tọ̀ ẹbọ sísun sórí i pẹpẹ rẹ̀.

11 Bùsi ohun ìní rẹ̀, Olúwa,

o tẹ́wọ́gbà iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.

Lu ẹgbẹ́ àwọn ó dìde i;

àwọn ó kórìíra rẹ̀,

wọn ó ṣe dìde mọ́."

12 ti Benjamini ó ,

"Jẹ́ olùfẹ́ Olúwa máa gbé àlàáfíà lọ́dọ̀ rẹ̀,

òun a máa ó gbogbo ọjọ́,

ẹni Olúwa fẹ́ràn yóò máa sinmi láàrín èjìká rẹ̀."

13 ti Josẹfu ó ,

"Olúwa bùkún ilẹ̀ rẹ,

fún ohun iyebíye láti ̀run pẹ̀ìrì

àti ibú ó ń bẹ níṣàlẹ̀;

14 àti fún èso iyebíye ̀run

àti ti ohun iyebíye ń dàgbà oṣooṣù;

15 pẹ̀ohun pàtàkì òkè ńlá ìgbàanì

àti fún ohun iyebíye ìgbà ayérayé;

16 Pẹ̀ohun iyebíye ayé àti ̀kún un rẹ̀

àti fún ìfẹ́ ẹni ó ń gbé inú igbó.

Jẹ́ gbogbo èyí sinmi orí Josẹfu,

lórí àtàrí ẹni ó yàtọ̀ láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀.

17 ọláńlá ó dàbí àkọ́akọ màlúù;

ìwo rẹ̀, ìwo àgbáǹréré ni.

Pẹ̀wọn ni yóò fi ti àwọn orílẹ̀-èdè,

pàápàá títí òpin ayé.

Àwọn ni ẹgbẹẹgbàárùn mẹ́wàá Efraimu,

àwọn ni ẹgbẹẹgbẹ̀rún Manase."

18 ti Sebuluni ó ,

"Yọ̀ Sebuluni, ti ìjáde lọ rẹ,

àti ìwọ Isakari, nínú àgọ́ rẹ.

19 Wọn yóò pe àwọn ènìyàn sórí òkè

àti níbẹ̀ wọn yóò ẹbọ òdodo,

wọn yóò mu nínú ̀pọ̀lọpọ̀ Òkun,

nínú ìṣúra ó pamọ́ nínú iyanrìn."

20 ti Gadi ó ,

"Ìbùkún ni ẹni ó Gadi gbilẹ̀!

Gadi ń gbé níbẹ̀ kìnnìún,

ó fa apá ya, àní àtàrí.

21 Ó yan ilẹ̀ ó dára fún ara rẹ̀;

ìpín olórí ni a fi fún un.

Nígbà ó gbogbo àwọn ènìyàn péjọ,

ó òdodo Olúwa ṣẹ,

àti ìdájọ́ rẹ̀ pẹ̀àwọn ọmọ Israẹli."

22 ti Dani ó ,

"Ọmọ kìnnìún ni Dani,

ń láti Baṣani ."

23 ti Naftali ó ,

"Ìwọ Naftali, kún fún ojúrere Ọlọ́run

àti ìbùkún Olúwa;

yóò jogún ìhà ìwọ̀-oòrùn àti gúúsù."

24 ti Aṣeri ó ,

"Ìbùkún ọmọ ni ti Aṣeri;

jẹ́ ó ojúrere láti ̀dọ̀ àwọn arákùnrin rẹ̀

ó ri ẹsẹ̀ rẹ̀ sínú òróró.

25 Bàtà rẹ̀ yóò jẹ́ irin àti idẹ,

agbára rẹ̀ yóò ọjọ́ rẹ̀.

26 "ẹlòmíràn Ọlọ́run Jeṣuruni,

ẹni ń gun ̀run fún ìrànlọ́wọ́ rẹ

àti ojú ̀run nínú ọláńlá rẹ̀.

27 Ọlọ́run ayérayé ni ibi ìsádi rẹ,

àti ìsàlẹ̀ ni apá ayérayé .

Yóò àwọn ̀rẹ níwájú rẹ,

ó , máa parun!

28 Israẹli nìkan yóò jókòó àlàáfíà,

orísun Jakọbu nìkan

ilẹ̀ ọkà àti ti ọtí wáìnì,

níbi ̀run ti ń sẹ ìrì sílẹ̀.

29 Ìbùkún ni fún , Israẹli,

ta ni ó dàbí rẹ,

ẹni a gbàlà láti ̀dọ̀ Olúwa?

Òun ni asà àti ìrànwọ́ rẹ̀

àti idà ọláńlá rẹ̀.

Àwọn ̀rẹ yóò tẹríba fún ,

ìwọ yóò tẹ ibi gíga wọn mọ́lẹ̀."

Veja também

Publicidade
Bíblia Online Bíblia Online

Bíblia Online • Versão: 2026-06-28_14-13-17-