Pular para o conteúdo
Publicidade

Juízes 4

Debora

1 Lẹ́yìn ikú Ehudu, àwọn ènìyàn Israẹli tún ṣẹ̀, wọ́n ṣe ohun ó burú ojú Olúwa. 2 Nítorí náà Olúwa jẹ́ Jabini, ọba àwọn Kenaani, ẹni ó jẹ ọba Hasori, ṣẹ́gun wọn. Orúkọ olórí ogun rẹ̀ ni Sisera ẹni ń gbé Haroseti-Hagoyimu. 3 Nítorí ó ̀́dẹ́gbẹ̀rún (900) kẹ̀kẹ́ ogun irin, ó ń pọ́n Israẹli lójú gidigidi fún ogún ọdún, Israẹli pe Olúwa fún ìrànlọ́wọ́.

4 Debora, wòlíì obìnrin, aya Lapidoti ni olórí àti aṣíwájú àwọn ará Israẹli àsìkò náà. 5 Òun a máa jókòó ṣe ìdájọ́ abẹ́ igi ̀pẹ a sọ orúkọ rẹ̀ ̀pẹ Debora láàrín Rama àti Beteli ilẹ̀ òkè Efraimu, àwọn ará Israẹli a máa ̀dọ̀ rẹ̀ láti yanjú èdè-àìyedè wọ́n ara wọn, tàbí láti gbọ́ ohùn Olúwa láti ẹnu rẹ̀. 6 ọjọ́ kan, ó ránṣẹ́ pe Baraki ọmọ Abinoamu, ẹni ń gbé Kedeṣi ilẹ̀ Naftali, ó fún un , "Olúwa, Ọlọ́run Israẹli pa á àṣẹ fún un , ó ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) àwọn akọni ọkùnrin jọ láti ̀Naftali àti ̀Sebuluni ẹgbẹ́ ogun, o síwájú wọn lọ òkè Tabori. 7 Èmi yóò fa Sisera olórí ogun Jabini, pẹ̀kẹ̀kẹ́ ogun rẹ àti àwọn ogun rẹ, odò Kiṣoni èmi yóò fi lọ́wọ́ ìwọ yóò ṣẹ́gun wọn níbẹ̀.’ "

8 Baraki a lóhùn , "Èmi yóò lọ ìwọ ó mi lọ, ṣùgbọ́n ìwọ yóò mi lọ, èmi yóò lọ."

9 Debora a lóhùn , "ó dára, èmi yóò lọ. Ṣùgbọ́n ọlá ìṣẹ́gun o ń lọ yìí jẹ́ tìrẹ, nítorí Olúwa yóò fi Sisera obìnrin lọ́wọ́," báyìí Debora Baraki lọ Kedeṣi. 10 Nígbà Baraki pe ̀Sebuluni àti ̀Naftali Kedeṣi ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) akíkanjú ọkùnrin ogun tẹ̀e, Debora pẹ̀wọn lọ.

11 Ǹjẹ́ Heberi ọmọ Keni, ti ya ara rẹ́ kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọmọ Keni, àní àwọn ọmọ Hobabu, àna Mose, ó pa àgọ́ rẹ̀ títí ibi igi óákù Saananimu, ó ni agbègbè Kedeṣi.

12 Nígbà a sọ fún Sisera Baraki ọmọ Abinoamu ti ogun jọ òkè Tabori, 13 Sisera gbogbo kẹ̀kẹ́ ogun irin rẹ̀ ṣe ̀́dẹ́gbẹ̀rún (900) àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun ó pẹ̀rẹ̀, láti Haroseti àwọn orílẹ̀-èdè odò Kiṣoni.

14 Debora fún Baraki , "Lọ! Lónìí ni Olúwa fi Sisera lọ́wọ́, Olúwa ti lọ síwájú rẹ." Baraki síwájú, àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) tẹ̀e lẹ́yìn, wọ́n kọjá òkè Tabori. 15 Olúwa ìdàrúdàpọ̀ àárín ogun Sisera, Olúwa fi ojú idà ṣẹ́gun Sisera àti àwọn oníkẹ̀kẹ́ ogun àti ọmọ-ogun orí ilẹ̀ iwájú Baraki. Sisera sọ̀kalẹ̀ lórí kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀ ó fi ẹsẹ̀ sálọ.

16 Baraki àti àwọn ogun rẹ̀ àwọn ̀náà, àwọn ọmọ-ogun orílẹ̀ àti àwọn kẹ̀kẹ́ ogun wọn títí Haroseti ti àwọn orílẹ̀-èdè, gbogbo ogun Sisera ti ojú idà ṣubú, ̀kan ó sálà tàbí ó láààyè. 17 Ṣùgbọ́n Sisera ti fi ẹsẹ̀ sálọ àgọ́ Jaeli aya Heberi ̀Keni: nítorí ìbá ̀rẹ́ àlàáfíà láàrín Jabini ọba Hasori àti ìdílé Heberi ti ̀Keni.

18 Jaeli jáde síta láti pàdé Sisera, ó fún un , "Wọlé sínú àgọ́ mi, Olúwa mi, wọlé ṣe bẹ̀nítorí ààbò ń bẹ fún ." Ó sínú àgọ́ rẹ̀, ó fi aṣọ ó.

19 Sisera , "Òrùngbẹ ń gbẹ́ , jọ̀wọ́ fún mi omi mu." Ó ṣí awọ wàrà kan, ó fún un mu ó tún daṣọ ó padà.

20 Sisera sọ fún Jaeli , "ó dúró ẹnu-ọ̀àgọ́, àti ẹnikẹ́ni béèrè bóyá òun níbẹ̀ ó sọ , ẹnìkankan ibẹ̀.’ "

21 Ṣùgbọ́n Jaeli ìyàwó Heberi ìṣó àgọ́ ó àti òòlù ọwọ́ rẹ̀, ó yọ́ wọ inú ibi ó sùn, nígbà ó ti sùn fọnfọn, nígbà náà ni ó kan ìṣó náà mọ́ òkè ìpéǹpéjú rẹ̀, ó wọlé ṣinṣin, ó .

22 Nígbà Baraki ó ti ń lépa Sisera, Jaeli láti pàdé rẹ̀, , èmi yóò fi ẹni ìwọ ń hàn ́, báyìí ni ó tẹ̀e wọ inú àgọ́ lọ, kíyèsi Sisera dùbúlẹ̀ síbẹ̀ pẹ̀ìṣó àgọ́ agbárí rẹ̀ a ti kàn mọ́lẹ̀ ṣinṣin ó ti .

23 ọjọ́ náà ni Ọlọ́run ṣẹ́gun Jabini ọba àwọn ará Kenaani iwájú àwọn ̀Israẹli. 24 Ọwọ́ àwọn ọmọ Israẹli le, ó ń lágbára síwájú àti síwájú i lára Jabini ọba Kenaani, títí wọ́n fi run òun àti àwọn ènìyàn rẹ̀.

Veja também