Pular para o conteúdo
Publicidade

Juízes 5

Orin Debora

1 Nígbà náà ni Debora àti Baraki ọmọ Abinoamu kọ orin ọjọ́ náà ,

2 "Nítorí àwọn olórí ti síwájú Israẹli,

nítorí bi àwọn ènìyàn ti fi tọkàntọkàn wa,

fi ìbùkún fún Olúwa!

3 "gbọ́ ̀yin ọba! fetí yín sílẹ̀ ̀yin ọmọ-aládé!

Èmi yóò kọrin Olúwa,

èmi yóò kọrin ìyìn Olúwa: Ọlọ́run Israẹli.

4 "Olúwa nígbà o jáde kúrò Seiri,

nígbà ìwọ ń yan jáde láti pápá Edomu,

ilẹ̀ tìtì, àwọn ̀run kán sílẹ̀,

àní àwọsánmọ̀ pẹ̀kàn omi sílẹ̀.

5 Àwọn òkè ńlá wárìrì iwájú Olúwa, bẹ́̀ ni Sinai iwájú Olúwa

Ọlọ́run Israẹli.

6 "ọjọ́ Ṣamgari ọmọ Anati,

ọjọ́ Jaeli, àwọn ̀òpópó ;

àwọn arìnrìn-àjò ń gba ̀ìkọ̀kọ̀.

7 Àwọn olórí tán Israẹli,

wọ́n tán, títí èmi Debora fi dìde

ìyá Israẹli.

8 Wọ́n ti yan ọlọ́run tuntun,

nígbà náà ni ogun ibodè

a ha asà tàbí ̀kọ̀ kan

láàrín ̀kẹ́ méjì (40,000) Israẹli .

9 Àyà mi àwọn aláṣẹ Israẹli

àwọn wọ́n yọ̀ǹda ara wọn tinútinú láàrín àwọn ènìyàn.

fi ìbùkún fún Olúwa!

10 "kéde rẹ̀: ̀yin ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ funfun,

̀yin ń jókòó lórí ẹní dáradára,

àti ̀yin ó ń rìn ̀.

̀jíjìn 11 ariwo àwọn tafàtafà, ibi a gbé ń fa omi.

Níbẹ̀ ni wọ́n gbé ń sọ ti iṣẹ́ òdodo Olúwa,

àní iṣẹ́ òdodo ìjọba rẹ̀ Israẹli.

"Nígbà náà ni àwọn ènìyàn Olúwa

sọ̀kalẹ̀ lọ ibodè.

12 , , Debora!

, , kọ orin dìde!

Dìde ìwọ Baraki!

àwọn ìgbèkùn rẹ ìgbèkùn ìwọ ọmọ Abinoamu.

13 "Nígbà náà ni àwọn tókù sọ̀kalẹ̀ àwọn ọlọ́lọ;

àwọn ènìyàn Olúwa tọ̀ pẹ̀àwọn alágbára.

14 Àwọn kan jáde láti Efraimu, àwọn gbòǹgbò wọn Amaleki;

Benjamini pẹ̀àwọn ó tẹ̀.

Láti Makiri ni àwọn aláṣẹ ti sọ̀kalẹ̀ ,

láti Sebuluni ni àwọn ẹni ń ̀oyè lọ́wọ́.

15 Àwọn ọmọ-aládé Isakari pẹ̀Debora;

Isakari ti ṣe olóòtítọ́ Baraki,

wọ́n fi ẹsẹ̀ súré tẹ̀wọn lọ àfonífojì náà.

ipadò Reubeni

ni ìgbèrò púpọ̀ .

16 Èéṣe ìwọ fi dúró pẹ́ láàrín agbo àgùntàn

láti máa gbọ́ fèrè olùṣọ́-àgùntàn?

ipadò Reubeni

ni ìgbèrò púpọ̀ .

17 Gileadi dúró òkè odò Jordani.

Èéṣe Dani fi dúró nínú ọkọ̀ ojú omi?

Aṣeri jókòó etí bèbè Òkun,

ó ń gbé èbúté rẹ̀.

18 Àwọn ènìyàn Sebuluni fi ̀wọn wéwu ikú;

bẹ́̀ ni àwọn ènìyàn Naftali ibi gíga pápá.

19 "Àwọn ọba , wọ́n ;

àwọn ọba Kenaani

Taanaki etí odo Megido,

ṣùgbọ́n wọn gba èrè owó.

20 Àwọn ìràwọ̀ láti ojú ̀run

láti inú ipa ̀wọn ni wọ́n Sisera .

21 Odò Kiṣoni gbá wọn lọ,

odò ìgbàanì, odò Kiṣoni.

Máa yan lọ, ìwọ ọkàn mi, nínú agbára!

22 Nígbà náà ni pátákò ẹsẹ̀ ẹṣin ki ilẹ̀,

nítorí eré sísá, eré sísá àwọn alágbára wọn.

23 fi Merosi ,ni angẹli Olúwa .

fi àwọn ènìyàn inú rẹ̀ ìbú kíkorò,

nítorí wọn ìrànlọ́wọ́ Olúwa,

láti dojúkọ àwọn alágbára.

24 "Ìbùkún ni fún Jaeli,

aya Heberi ará Keni ju àwọn obìnrin lọ,

ìbùkún ni fún un ju àwọn obìnrin ń gbé nínú àgọ́.

25 Ó béèrè omi, ó fún un wàrà;

ó òrí-àmọ́ tọ̀ ́ nínú àwo iyebíye ó yẹ fún àwọn ọlọ́.

26 Ó na ọwọ́ rẹ̀ ìṣó àgọ́,

ó fi ọwọ́ ̀tún rẹ̀ òòlù awọ gbẹ́nàgbẹ́,

òòlù náà ni ó fi lu Sisera, ó gbá a mọ́ ọn orí,

ó gun, ó kàn ̀bátí rẹ̀ mọ́lẹ̀ ṣinṣin.

27 ẹsẹ̀ rẹ̀ ó wólẹ̀,

ó ṣubú; ó dùbúlẹ̀.

Ó wólẹ̀ ẹsẹ̀ rẹ̀, ó ṣubú níbi ó gbé ń wólẹ̀;

níbẹ̀ náà ni ó ṣubú .

28 "Ìyá Sisera yọjú láti ojú fèrèsé,

ó kígbe, ó kígbe ojú fèrèsé ọlọ́,

Èéṣe kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ fi pẹ́ bẹ́̀ láti ?

Èéṣe ẹsẹ̀ kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀ fi dúró lẹ́yìn?

29 Àwọn amòye obìnrin rẹ̀ a lóhùn;

àní òun náà pẹ̀ti ara rẹ̀ lóhùn ,

30 Wọn ha ń wa kiri, wọn ha ti pín ìkógun bi:

ọmọbìnrin kan tàbí méjì fún ọkùnrin kan,

fún Sisera ìkógun aṣọ aláràbarà,

ìkógun aṣọ aláràbarà àti ọlọ́,

àwọn aṣọ ọlọ́iyebíye fún ọrùn mi,

gbogbo èyí a ogun?

31 5.31: If 1.16. "Bẹ́̀ ni ó jẹ́ gbogbo àwọn ̀rẹ ó ṣègbé Olúwa!

Ṣùgbọ́n jẹ́ àwọn ó fẹ́ ràn oòrùn,

nígbà ó yọ nínú agbára rẹ̀."

Ilẹ̀ náà sinmi ogójì ọdún.

Veja também