Pular para o conteúdo
Publicidade

Onidajọ 7

Gideoni ṣẹ́gun àwọn ará Midiani

1 òwúrọ̀ kùtùkùtù Jerubbaali (èyí ni Gideoni) pẹ̀gbogbo àwọn ọmọ-ogun ó pẹ̀rẹ̀ ogun jọ lẹ́bàá a orísun Harodi. Àwọn ogun Midiani apá àríwá wọ́n àfonífojì ó ̀òkè More. 2 Olúwa fún Gideoni , "Àwọn ọmọ-ogun o kójọ sọ́dọ̀ ti pọ̀fún mi láti fi àwọn ogun Midiani wọn lọ́wọ́, Israẹli ba à gbé ara rẹ̀ ga mi agbára òun ni ó gbà á , 3 kéde àwọn ènìyàn nísinsin yìí , Ẹnikẹ́ni ó ń gbọ̀n, ó ń bẹ̀padà sẹ́yìn, ó kúrò lórí òkè Gileadi.’ " Báyìí ni Gideoni ṣe ya àwọn ènìyàn náà. Ẹgbẹ̀rún méjìlélógún (22,000) ọkùnrin padà sẹ́yìn àwọn ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) dúró.

4 Olúwa tún sọ fún Gideoni , "Àwọn ènìyàn yìí tún pọ̀. wọn lọ ibi omi , èmi yóò yọ̀rọ̀ wọn níbẹ̀ fún . mo eléyìí yóò lọ yóò lọ, ṣùgbọ́n mo sọ , Eléyìí lọ,òun gbọdọ̀ lọ."

5 Gideoni àwọn ọkùnrin náà lọ ibi ìsun omi. Níbẹ̀ ni Olúwa ti fún un , "ó pín àwọn ènìyàn náà ̀méjì. Ya àwọn ó fi ahọ́n wọn omi ajá kúrò lára àwọn ó kúnlẹ̀ láti mu omi pẹ̀ọwọ́ wọn." 6 ̀́dúnrún (300) ọkùnrin ni ó omi pẹ̀ahọ́n wọn. Gbogbo àwọn ìyókù ni ó kúnlẹ̀ láti mu mi.

7 Olúwa fún Gideoni , "Àwọn ̀́dúnrún (300) ọkùnrin ó omi ni èmi yóò láti gbà yín àti láti fi ogun Midiani yín lọ́wọ́. Jẹ́ àwọn tókù padà ilé wọn." 8 Báyìí ni Gideoni ṣe àwọn Israẹli ó padà àgọ́ wọn, ṣùgbọ́n ó àwọn ̀́dúnrún (300) ọkùnrin náà dúró. Àwọn wọ̀nyí gba gbogbo ohun èlò àti fèrè àwọn ó ti padà.

Ibùdó ogun àwọn Midiani àfonífojì ìsàlẹ̀. Ibi ó . 9 òru ọjọ́ náà Olúwa sọ fún Gideoni , "Dìde, dojú ogun kọ ibùdó ogun àwọn ará Midiani nítorí èmi yóò fi lọ́wọ́. 10 Ṣùgbọ́n ̀àti kọlù wọ́n ń ́, yọ́ wọ ibùdó wọn lọ o Pura ìránṣẹ́ rẹ lọ́wọ́ 11 o fi ara balẹ̀ gbọ́ ohun wọ́n ń sọ nínú ibùdó náà. Lẹ́yìn èyí ọkàn rẹ̀ yóò le láti kọlù ibùdó náà." Báyìí ni òun àti Pura ìránṣẹ́ rẹ̀ wọ ẹnu-ọ̀ibùdó yìí. 12 Àwọn ará Midiani, àwọn ará Amaleki àti gbogbo ènìyàn ìlà-oòrùn lọ àfonífojì eṣú ni wọ́n nítorí púpọ̀ wọn. Àwọn ìbákasẹ wọn lóǹkà, wọ́n pọ̀ yanrìn inú Òkun.

13 Gideoni àsìkò ọkùnrin kan bẹ̀rẹ̀ í rọ́ àlá ó ̀kan nínú àwọn ̀rẹ́ rẹ̀. Ó , "Mo àlá kan, nínú àlá náà mo àkàrà kan ṣe róbótó a fi barle ṣe ń wọ inú ibùdó àwọn ará Midiani, ó kọlu àgọ́ pẹ̀agbára ńlá bi àgọ́ náà dojúdé, ó ṣubú."

14 ̀rẹ́ rẹ̀ a lóhùn , "Èyí le túmọ̀ ohun mìíràn ju idà Gideoni ọmọ Joaṣi ará Israẹli lọ: Ọlọ́run ti fi àwọn ará Midiani àti gbogbo ogun ibùdó e lọ́wọ́."

15 Nígbà Gideoni gbọ́ àlá náà àti ìtumọ̀ rẹ̀, ó wólẹ̀ sin Ọlọ́run: lẹ́yìn náà ni ó padà ibùdó àwọn ọmọ Israẹli ó wọ́n , "dìde! Nítorí Olúwa yóò yín láti ṣẹ́gun gbogbo ogun Midiani." 16 Nígbà ó ti pín àwọn ̀́dúnrún (300) ọkùnrin wọ̀n-ọn-nì ̀mẹ́ta, ó fi fèrè, pẹ̀àwọn òfìfo ìkòkò ẹnìkọ̀̀kan wọn lọ́wọ́, iná nínú àwọn ìkòkò náà.

17 Ó sọ fún wọn , "máa , máa ṣe ohun mo ṣe. Nígbà mo igun ibùdó wọn ṣe ohun mo ṣe. 18 Nígbà èmi àti àwọn ọkùnrin ó pẹ̀mi fun fèrè wa, bẹ́̀ ni ̀yin náà ni gbogbo igun ibùdó ̀ fun àwọn fèrè yín , Fún Olúwa àti fún Gideoni.’ "

19 Gideoni àti àwọn ọgọ́rùn-ún ọkùnrin ó pẹ̀rẹ̀ òpin ibùdó àwọn ará Midiani nǹkan agogo méjìlá padà. Wọ́n fun fèrè wọn, wọ́n tún fọ́ àwọn ìkòkò ó ọwọ́ mọ́lẹ̀. 20 Àwọn ẹgbẹ́ mẹ́tẹ̀̀ta fun fèrè wọn, wọ́n tún fọ́ àwọn ìkòkò wọn mọ́lẹ̀. Wọ́n àwọn fìtílà iná wọn ọwọ́ òsì wọn àti fèrè wọ́n ń fun ọwọ́ ̀tún wọn. Wọ́n pariwo è , "Idà kan fún Olúwa àti fún Gideoni!" 21 Nígbà ọkùnrin kọ̀̀kan dúró ipò rẹ̀ ibùdó àwọn Midiani , gbogbo àwọn ọmọ-ogun Midiani ń káàkiri, wọ́n ń pariwo wọ́n ṣe ń sálọ.

22 Nígbà àwọn ̀́dúnrún (300) ọkùnrin wọ̀n-ọn-nì fun fèrè wọn, Olúwa ojú idà ọkùnrin kọ̀̀kan padà ẹnìkejì rẹ̀ àti gbogbo ogun wọn. Àwọn ọmọ-ogun títí Beti-Sitta ̀Serera títí lọ ìpínlẹ̀ Abeli-Mehola ̀Tabbati. 23 Gbogbo àwọn ọmọ-ogun Israẹli láti ̀Naftali, Aṣeri àti gbogbo Manase ni Gideoni ránṣẹ́ si, wọ́n wọ́n àwọn ará Midiani. 24 Gideoni tún ránṣẹ́ gbogbo àwọn ìlú ó orí òkè Efraimu , "jáde àwọn ará Midiani , tètè gba àwọn omi Jordani títí Beti-Bara wọ́n bẹ̀."

Báyìí ni a ṣe pe gbogbo ọkùnrin ológun Efraimu jáde wọ́n gba gbogbo àwọn à wọ odò Jordani títí Beti-Bara. 25 Wọ́n méjì nínú àwọn olórí àwọn ará Midiani, àwọn náà ni Orebu àti Seebu. Wọ́n pa Horebu nínú àpáta Orebu, wọ́n pa Seebu níbi àwọn ènìyàn ti mọ̀ fún wáìnì a ń ìfúntí Seebu. Wọ́n àwọn ará Midiani, nígbà wọ́n gbé orí Orebu àti Seebu tọ Gideoni ẹni ó apá kejì Jordani.

Veja também